Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 5

1 Nígbà gbogbo iṣẹ́ Solomoni ti ṣe fún tẹmpili Olúwa ti parí, ó gbogbo àwọn nǹkan Dafidi baba rẹ̀ ti sọ́tọ̀: wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun èlò ̀ṣọ́, ó fi wọ́n sínú ìṣúra ilé Ọlọ́run.

A gbé àpótí ̀wọ inú tẹmpili

2 Nígbà náà ni Solomoni pe àwọn àgbàgbà Israẹli jọ Jerusalẹmu, gbogbo àwọn olórí ̀kọ̀̀kan àti àwọn olóyè àwọn ìdílé Israẹli, wọn ó gbé àpótí ̀Olúwa gòkè láti Sioni ìlú Dafidi. 3 Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli péjọ ̀dọ̀ ọba àkókò àjọ àgọ́.

4 Gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli , àwọn ọmọ Lefi gbé àpótí ̀Olúwa. 5 Wọ́n gbé àpótí ̀náà gòkè àti àgọ́ ìpàdé àti gbogbo ohun èlò mímọ́ ó nínú àgọ́. Àwọn àlùfáà wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi ni ó wọn gòkè . 6 Nígbà náà ni ọba Solomoni àti gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli ó péjọ ̀dọ̀ rẹ̀, níwájú àpótí ̀náà wọ́n fi àgùntàn àti màlúù a le è tán ẹbọ, bẹ́̀ ni a le è mọ iye wọn tán nítorí wọ́n ti pọ̀ .

7 Nígbà náà ni àwọn àlùfáà gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa ipò rẹ̀, ibi inú lọ́hùn ún ilé Olúwa, Ibi Mímọ́ Jùlọ, wọ́n gbé e abẹ́ ìyẹ́ àwọn kérúbù. 8 Àwọn Kérúbù na ìyẹ́ wọn bo ibi àpótí ̀náà àti àwọn ̀ó gbé e . 9 Àwọn ̀rẹ̀ náà gùn bẹ́̀ a fi orí àwọn ̀náà láti ibi àpótí ̀náà níwájú Ibi Mímọ́ náà, ṣùgbọ́n a wọn lóde. Níbẹ̀ ni ó títí di òní yìí. 10 ohun kan nínú àpótí ̀náà ṣe wàláà méjì Mose fi sínú rẹ̀ Horebu, ìgbà Olúwa fi àwọn ọmọ Israẹli májẹ̀lẹ́yìn ìgbà wọ́n jáde láti ilẹ̀ Ejibiti.

11 Lẹ́yìn náà ni àwọn àlùfáà jáde láti Ibi Mímọ́. Gbogbo àwọn àlùfáà ó níbẹ̀ ni ó ya ara wọn mímọ́ láìbìkítà fún ìpín wọn. 12 Gbogbo àwọn ọmọ Lefi wọ́n jẹ́ akọrin: Asafu, Hemani, Jedutuni àti àwọn ọmọ wọn àti àwọn ẹbí wọn, wọ́n dúró igun ìlà-oòrùn pẹpẹ náà wọ́n wọ aṣọ ̀gbọ̀ tuntun wọ́n ń lo kimbali, dùùrù àti ohun èlò orin olókùn. Ìwọ̀n ọgọ́àwọn àlùfáà wọ́n ń fun ìpè ni wọ́n tẹ̀wọn. 13 5.13,14: 1Ọb 8.10-11.Àwọn afùnpè àti àwọn akọrin pa ohùn wọn pọ̀ ̀kan ṣoṣo, láti fi ìyìn àti ọpẹ́ fun Olúwa. Wọ́n fi ìpè, kimbali àti àwọn ohun èlò orin mìíràn mọ́ ọn, wọ́n gbé ohùn wọn sókè láti fi yin Olúwa, wọ́n ń kọrin ,

"Ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ títí láéláé."

Nígbà náà ni ìkùùkuu ojú ̀run kún inú tẹmpili Olúwa, 14 bẹ́̀ àwọn àlùfáà le è ṣiṣẹ́ ìsìn wọn nítorí ìkùùkuu náà, nítorí ògo Olúwa kún inú tẹmpili Ọlọ́run.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também