Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 17

1 Èyí ìpín ̀Manase í ṣe àkọ́Josẹfu, fún Makiri, àkọ́Manase. Makiri ni baba ńlá àwọn ọmọ Gileadi, ó ti gba Gileadi àti Baṣani nítorí àwọn ọmọ Makiri jẹ́ jagunjagun ńlá. 2 Nítorí náà ìpín yìí fún ìyókù àwọn ènìyàn Manase: agbo ilé Abieseri, Heleki, Asrieli, Ṣekemu, Heferi àti Ṣemida. Ìwọ̀nyí àwọn ọmọ ọkùnrin Manase ọmọ Josẹfu agbo ilé wọn.

3 17.3,4: Nu 26.33; 27.1-7. Nísinsin yìí Selofehadi ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri, ọmọ Manase, ọmọkùnrin, ṣe àwọn ọmọbìnrin, orúkọ wọn jẹ́: Mahila, Noa, Hogla, Milka àti Tirsa. 4 Wọ́n lọ Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni, àti àwọn olórí , "Olúwa pàṣẹ fún Mose láti fún wa ìní àárín àwọn arákùnrin wa." Bẹ́̀ ni Joṣua fún wọn ìní pẹ̀àwọn arákùnrin baba wọn, gẹ́gẹ́ àṣẹ Olúwa. 5 Ìpín ilẹ̀ Manase jẹ́ ìsọ̀mẹ́wàá ̀Gileadi àti Baṣani ìlà-oòrùn Jordani, 6 nítorí àwọn ọmọbìnrin ̀Manase gba ìní àárín àwọn ọmọkùnrin. Ilẹ̀ Gileadi jẹ́ ti ìyókù àwọn ọmọ Manase.

7 Agbègbè Manase fẹ̀ láti Aṣeri títí Mikmeta ìlà-oòrùn Ṣekemu. Ààlà rẹ̀ lọ ìhà gúúsù títí fi ibi àwọn ènìyàn ń gbé Tapua, 8 (Manase lo ni ilẹ̀ Tapua, ṣùgbọ́n Tapua fúnra rẹ̀ to ni ààlà ilẹ̀ Manase jẹ ti àwọn ará Efraimu.) 9 Ààlà rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ odò Kana, ìhà gúúsù odò náà. Àwọn ìlú ó jẹ́ ti Efraimu àárín àwọn ìlú Manase, ṣùgbọ́n ààlà Manase ni ìhà àríwá odò náà, ó yọ Òkun. 10 Ìhà gúúsù ilẹ̀ náà jẹ́ ti Efraimu, ṣùgbọ́n ìhà àríwá jẹ́ ti Manase. Ilẹ̀ Manase Òkun, Aṣeri jẹ́ ààlà rẹ̀ àríwá, nígbà Isakari jẹ́ ààlà ti ìlà-oòrùn.

11 17.11-13: On 1.27-28. àárín Isakari àti Aṣeri, Manase tún ni Beti-Ṣeani, Ibleamu àti àwọn ènìyàn Dori, Endori, Taanaki àti Megido pẹ̀àwọn abúlé ó wọn (̀kẹ́ta nínú orúkọ wọn Nafoti).

12 Síbẹ̀, àwọn ọmọ Manase gba àwọn ìlú wọ̀nyí, nítorí àwọn ará Kenaani ti pinnu láti gbé ilẹ̀ náà. 13 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn ará Israẹli di alágbára, wọ́n àwọn ọmọ Kenaani sìn, ṣùgbọ́n wọn wọn jáde pátápátá.

14 Àwọn ọmọ Josẹfu fún Joṣua , "Èéṣe ìwọ fi fún wa ìpín ilẹ̀ kan àti ìdákan ìní? Nítorí àwa jẹ́ ̀pọ̀ ènìyàn Olúwa ti bùkún lọ́pọ̀lọ́pọ̀."

15 Joṣua wọn lóhùn , "pọ̀ bẹ́̀, òkè ìlú Efraimu kéré fún yin, gòkè lọ igbó ṣán ilẹ̀ òkè fún ara yín ibẹ̀ ilẹ̀ àwọn ará Peresi àti ará Refaimu."

16 Àwọn ènìyàn Josẹfu dáhùn , "Òkè fún wa, bẹ́̀ ni gbogbo àwọn ará Kenaani ó gbé pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti gbogbo àwọn ń bẹ Beti-Ṣeani àti àwọn ìletò àti àwọn ń gbé àfonífojì Jesreeli kẹ̀kẹ́ ogun onírin."

17 Ṣùgbọ́n Joṣua sọ fún àwọn ilé Josẹfu: fún Efraimu àti Manase , "Lóòtítọ́ ni pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀, jẹ́ alágbára. ̀yin yóò ìpín kan ṣoṣo. 18 Ṣùgbọ́n ilẹ̀ orí òkè igbó jẹ́ tiyín pẹ̀. ṣán ilẹ̀ náà, òpin rẹ̀ yóò jẹ́ tiyín pátápátá. ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn ará Kenaani kẹ̀kẹ́ ogun irin, ó jẹ́ wọ́n agbára, síbẹ̀ wọn jáde."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também