Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 8

Ìparun Ai

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Joṣua , "ṣe bẹ̀, àyà ó ṣe ́. gbogbo àwọn ọmọ-ogun pẹ̀rẹ, gòkè lọ gbógun ti Ai. Nítorí mo ti fi ọba Ai, àwọn ènìyàn rẹ̀, ìlú u rẹ̀ àti ilẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́. 2 Ìwọ yóò ṣe Ai àti ọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ ìwọ ti ṣe Jeriko àti ọba rẹ̀, ohun ìkógun wọn àti ohun ̀sìn wọn ni ̀yin fún ara yín. Rán ènìyàn wọ́n ba ̀yìn ìlú náà."

3 Bẹ́̀ Joṣua àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun jáde lọ láti dojúkọ Ai. Ó yan ẹgbàá mẹ́̀́dógún (30,000) àwọn ọkùnrin ogun rẹ̀ ti ó yakin, ó rán wọn lọ òru. 4 Pẹ̀àwọn àṣẹ wọ̀nyí: "fi etí sílẹ̀ dáradára. ba ̀yìn ìlú náà. ṣe jìnnà i púpọ̀. gbogbo yín ìmúrasílẹ̀. 5 Èmi àti gbogbo àwọn ó pẹ̀mi yóò súnmọ́ ìlú náà, nígbà àwọn ọkùnrin náà jáde wa, gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe ìṣáájú, àwa yóò kúrò níwájú u wọn. 6 Wọn yóò lépa wa títí àwa ó fi tàn wọ́n jáde kúrò ìlú náà, nítorí wọn yóò , wọ́n ń sálọ kúrò ̀dọ̀ wa gẹ́gẹ́ wọ́n ṣe ìṣáájú. Nítorí náà a kúrò fún wọn, 7 ̀yin yóò dìde kúrò ibùba, ó gba ìlú náà. Olúwa Ọlọ́run yín yóò fi e yín lọ́wọ́. 8 Nígbà ti gba ìlú náà, ti iná bọ̀ ́. ṣe ohun Olúwa pàṣẹ. Mo ti fi àṣẹ fún un yín ."

9 Nígbà náà ni Joṣua rán wọn lọ. Wọ́n lọ ibùba, wọ́n sùn àárín Beteli àti Ai, ìwọ̀-oòrùn Ai. Ṣùgbọ́n Joṣua dúró pẹ̀àwọn ènìyàn òru ọjọ́ náà.

10 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì Joṣua àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, òun àti àwọn olórí Israẹli, wọ́n wọ́de ogun lọ Ai. 11 Gbogbo àwọn ọmọ-ogun ó pẹ̀u rẹ̀ gòkè lọ, wọ́n súnmọ́ tòsí ìlú náà, wọ́n iwájú u rẹ̀. Wọ́n pàgọ́ ìhà àríwá Ai. Àfonífojì agbede-méjì wọn àti ìlú náà. 12 Joṣua ti fi ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ọmọ-ogun pamọ́ àárín Beteli àti Ai, ìwọ̀-oòrùn ìlú náà. 13 Wọ́n yan àwọn ọmọ-ogun ipò wọn, gbogbo àwọn ó ibùdó lọ àríwá ìlú náà àti àwọn ó pamọ́ ìwọ̀-oòrùn rẹ̀. òru ọjọ́ náà Joṣua lọ àfonífojì.

14 Nígbà ọba Ai èyí, òun àti gbogbo ọkùnrin ìlú náà yára jáde òwúrọ̀ kùtùkùtù láti pàdé ogun Israẹli pẹ̀tẹ́lẹ̀ aginjù. Ṣùgbọ́n mọ̀ àwọn kan ibùba ̀yìn ìlú náà. 15 Joṣua àti gbogbo àwọn Israẹli ṣe ẹni a padà níwájú wọn, wọ́n gba ̀aginjù. 16 A pe gbogbo àwọn ọkùnrin Ai jọ láti lépa wọn, wọ́n lépa Joṣua títí wọ́n fi tàn wọ́n jáde nínú ìlú náà. 17 ku ọkùnrin kan Ai tàbí Beteli tẹ̀Israẹli. Wọ́n fi ìlẹ̀kùn ibodè ìlú náà sílẹ̀ ṣíṣí, wọ́n ń lépa àwọn ará Israẹli.

18 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Joṣua , "Na ̀kọ̀ ó lọ́wọ́ rẹ Ai, nítorí èmi yóò fi ìlú náà ọwọ́." Bẹ́̀ ni Joṣua na ̀kọ̀ ọwọ́ rẹ̀ Ai. 19 ó ti ṣe èyí tán, àwọn ọkùnrin ó ba dìde kánkán kúrò ipò wọn, wọ́n sáré síwájú. Wọn wọ ìlú náà, wọ́n gbà á, wọ́n yára ti iná bọ̀ ́.

20 Àwọn ọkùnrin Ai bojú wo ̀yìn, wọ́n èéfín ìlú náà ń gòkè lọ ̀run, ṣùgbọ́n wọn , ààyè láti àsálà lọ ibìkan kan, nítorí àwọn ará Israẹli wọ́n ń sálọ aginjù ti yípadà àwọn ń lépa wọn. 21 Nígbà Joṣua àti gbogbo àwọn ará Israẹli i àwọn ó ti gba ìlú náà, èéfín ìlú náà ń gòkè, wọ́n padà wọ́n kọlu àwọn ọkùnrin Ai. 22 Àwọn ọmọ-ogun ó ba náà yípadà wọn láti inú ìlú náà, bẹ́̀ ni wọ́n agbede-méjì àwọn ará Israẹli ìhà méjèèjì. Israẹli pa wọ́n, bẹ́̀ ni wọn jẹ́ ̀kan ó tàbí ó sálọ nínú wọn. 23 Ṣùgbọ́n wọ́n ọba Ai láààyè, wọ́n mu un tọ Joṣua .

24 Nígbà Israẹli parí pípa gbogbo àwọn ìlú Ai pápá àti aginjù ibi wọ́n ti lépa wọn lọ, gbogbo wọ́n ti ojú idà ṣubú, a fi pa gbogbo wọn tan, gbogbo àwọn Israẹli padà Ai, wọ́n fi ojú idà kọlù ú. 25 Ẹgbàá mẹ́(12,000) ọkùnrin àti obìnrin ni ó ọjọ́ náàgbogbo wọn jẹ́ àwọn ènìyàn Ai. 26 Nítorí Joṣua fa ọwọ́ rẹ̀ ó di ̀kọ̀ ̀yìn, títí ó fi pa gbogbo àwọn ń gbé ìlú Ai run. 27 Ṣùgbọ́n Israẹli ẹran ̀sìn àti ìkógun ti ìlú yìí fún ara wọn, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Joṣua.

28 Joṣua Ai, ó sọ ́ di ààtàn, àní ahoro di òní yìí. 29 Ó gbé ọba Ai kọ́ orí igi, ó fi kalẹ̀ síbẹ̀ títí di ìrọ̀lẹ́. oòrùn ti wọ̀ ni Joṣua pàṣẹ fún wọn láti sọ òkú rẹ̀ kalẹ̀ kúrò orí igi, wọn wọ́ àtiwọ ẹnu ibodè ìlú náà. Wọ́n òkìtì òkúta ńlá e orí, èyí ó títí di òní yìí.

Májẹ̀a sọ di ̀tun orí òkè Ebali

30 8.30-35: De 27.2-8. Nígbà náà ni Joṣua mọ pẹpẹ kan fún Olúwa Ọlọ́run Israẹli, òkè Ebali, 31 gẹ́gẹ́ Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli. Ó kọ́ ́ gẹ́gẹ́ a ti kọ́ nínú ìwé òfin Mose, pẹpẹ odindi òkúta, èyí ẹnìkan fi ohun èlò irin kàn . Wọ́n ọrẹ ẹbọ sísun àti ọrẹ àlàáfíà orí rẹ̀ Olúwa. 32 Níbẹ̀, ojú àwọn ará Israẹli, Joṣua ṣe àdàkọ òfin Mose èyí ó ti kọ ara òkúta náà. 33 Gbogbo Israẹli, àjèjì àti ọmọ ìlú, pẹ̀àwọn àgbàgbà, olórí àti onídàájọ́ dúró ̀gbẹ́ méjèèjì àpótí ̀Olúwa ó kọjú àwọn àlùfáà ó ú, wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi. Ìdajì àwọn ènìyàn náà dúró òkè Gerisimu, àwọn ìdajì si dúró ni òkè Ebali, gẹ́gẹ́ Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pàṣẹ , wọn súre fún àwọn ènìyàn Israẹli.

34 Lẹ́yìn èyí, Joṣua ka gbogbo ̀rọ̀ inú òfin, ìbùkún àti ègún, gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú ìwé òfin. 35 ̀rọ̀ kan nínú gbogbo èyí Mose pàṣẹ Joṣua iwájú gbogbo àjọ Israẹli, títí fi kan àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ wọn, àti àwọn àjèjì ń gbé àárín wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também