Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 7

̀ṣẹ̀ Akani

1 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli ṣe àìṣòótọ́ nípa ohun ìyàsọ́tọ̀, Akani ọmọ Karmi, ọmọ Sabdi, ọmọ Sera, ̀Juda, nínú wọn. Bẹ́̀ ni ìbínú Olúwa ru àwọn ará Israẹli.

2 Joṣua rán àwọn ọkùnrin láti Jeriko lọ Ai, ó súnmọ́ Beti-Afeni ìlà-oòrùn Beteli, ó sọ fún wọn , "gòkè lọ ṣe ayọ́lẹ̀." Bẹ́̀ ni àwọn arákùnrin náà lọ, wọ́n yọ́ Ai .

3 Nígbà wọ́n padà ̀dọ̀ Joṣua, wọ́n , "í ṣe gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ni láti gòkè lọ Ai . Rán ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) tàbí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) ọkùnrin láti gbà á, ó ṣe gbogbo àwọn ènìyàn agara, nítorí ìba ọkùnrin díẹ̀ ó níbẹ̀." 4 Bẹ́̀ àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) ọkùnrin lọ; ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Ai wọn . 5 Àwọn ènìyàn Ai pa àwọn mẹ́rìndínlógójì nínú wọn. Wọ́n ń lépa àwọn ará Israẹli láti ibodè ìlú títí Ṣebarimu, wọ́n pa àwọn ń sọ̀kalẹ̀. Àyà àwọn ènìyàn náà , ọkàn wọn pami.

6 Joṣua fa aṣọ rẹ̀ ya, ó dojúbolẹ̀ níwájú àpótí ̀Olúwa títí di àṣálẹ́. Àwọn àgbà Israẹli ṣe bákan náà, wọ́n ku eruku orí wọn. 7 Joṣua , "Háà, Olúwa Olódùmarè, nítorí kín ni ìwọ ṣe àwọn ènìyàn yìí kọjá Jordani, láti fi wọ́n àwọn ará Amori lọ́wọ́, láti pa wọn run? Àwa ìbá mọ̀ a dúró òdìkejì Jordani? 8 Olúwa, kín ni èmi yóò sọ nísinsin yìí Israẹli ti níwájú ̀a rẹ̀? 9 Àwọn Kenaani àti àwọn ènìyàn ìlú ó náà yóò gbọ́ èyí, wọn yóò wa , wọn yóò orúkọ wa kúrò ayé. ni ìwọ ó ha ṣe fún orúkọ ńlá à rẹ?"

10 Olúwa sọ fún Joṣua , "Dìde! Kín ni ìwọ ń ṣe ó fi dojúbolẹ̀? 11 Israẹli ti ṣẹ̀, wọ́n ti ba májẹ̀mi jẹ́, èyí mo pàṣẹ fún wọn wọn pamọ́. Wọ́n ti nínú ohun ìyàsọ́tọ̀, wọ́n ti , wọ́n pa irọ́, wọ́n ti fi wọ́n ara ohun ìní wọn. 12 Ìdí èyí àwọn ará Israẹli fi dúró níwájú àwọn ̀wọn; wọ́n ̀yìn wọn padà, wọ́n sálọ níwájú ̀a wọn nítorí àwọn gan an ti di ẹni ìparun. Èmi yóò pẹ̀u yín mọ́, ṣe ̀yin pa ohun ìyàsọ́tọ̀ run kúrò àárín yín.

13 "Lọ, ya àwọn ènìyàn náà mímọ́. Sọ fún wọn , ya ara yín mímọ́ fún ̀la, nítorí báyìí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli , ohun ìyàsọ́tọ̀ kan ń bẹ àárín yín, Israẹli. ̀yin yóò dúró níwájú àwọn ̀a yín títí ̀yin yóò fi kúrò.

14 " òwúrọ̀, ará yín síwájú ̀kọ̀̀kan. ̀Olúwa yóò iwájú agbo ilé kọ̀̀kan, agbo ilé Olúwa yóò iwájú ìdílé kọ̀̀kan, ìdílé Olúwa yóò iwájú ẹni kọ̀̀kan. 15 Ẹnikẹ́ni a mọ́ pẹ̀ohun ìyàsọ́tọ̀ náà, a ó fi iná pa á run, pẹ̀gbogbo ohun ó . Ó ti ba májẹ̀Olúwa jẹ́, ó ti ṣe nǹkan ìtìjú Israẹli!’ "

16 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Joṣua Israẹli síwájú ̀kọ̀̀kan, a ̀Juda. 17 Àwọn agbo ilé e Juda iwájú, ó agbo ilé Sera. Ó agbo ilé Sera síwájú ìdílé kọ̀̀kan, a ìdílé Sabdi. 18 Joṣua ìdílé Simri síwájú ọkùnrin kọ̀̀kan, a Akani ọmọ Karmi, ọmọ Sabdi, ọmọ Sera ti ̀Juda.

19 Nígbà náà Joṣua sọ fún Akani , "Ọmọ mi fi ògo fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, o fi ìyìn fún un. Sọ fún mi ohun ìwọ ti ṣe, ṣe fi pamọ́ fún mi."

20 Akani dáhùn , "Òtítọ́ ni! Mo ti ṣẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. Nǹkan mo ṣe nìyìí, 21 nígbà mo ̀Babeli kan ó dára nínú ìkógun, àti igba ṣékélì fàdákà àti odindi wúrà olóṣùnwọ́n àádọ́ta ṣékélì, mo ṣe ojúkòkòrò wọn mo wọn. Mo fi wọ́n pamọ́ abẹ́ àgọ́ mi àti fàdákà abẹ́ rẹ̀."

22 Bẹ́̀ ni Joṣua ran àwọn òjíṣẹ́, wọ́n sáré wọ inú àgọ́ náà, ó níbẹ̀, a fi pamọ́ nínú àgọ́ rẹ̀, àti fàdákà abẹ́ rẹ̀. 23 Wọ́n àwọn nǹkan náà jáde láti inú àgọ́ rẹ̀, wọ́n wọn fún Joṣua àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n fi wọ́n lélẹ̀ níwájú Olúwa.

24 Nígbà náà ni Joṣua pẹ̀gbogbo Israẹli, Akani ọmọ Sera, fàdákà, ̀àti wúrà a , àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin àti obìnrin, màlúù rẹ̀, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti àgùntàn àgọ́ rẹ̀ àti gbogbo ohun ó ni, wọ́n wọn lọ ibi àfonífojì Akori. 25 Joṣua , "Èéṣe ìwọ wàhálà yìí orí wa? Olúwa yóò ìpọ́njú orí ìwọ náà lónìí."

Nígbà náà ni gbogbo Israẹli sọ ́ òkúta pa, lẹ́yìn ìgbà wọ́n sọ àwọn tókù òkúta pa tán, wọ́n wọn níná. 26 Wọ́n òkìtì òkúta ńlá Akani lórí títí di òní yìí. Nígbà náà Olúwa ìbínú gbígbóná rẹ̀ padà. Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ ibẹ̀ àfonífojì Akori láti ìgbà náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também