Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 20

Àwọn ìlú ààbò

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Joṣua , 2 20.2-9: Nu 35.6-34; De 4.41-43; 19.1-13."Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli wọn yan àwọn ìlú ààbò, gẹ́gẹ́ mo ti pàṣẹ fún láti ẹnu Mose, 3 ẹni ó ṣèèṣì pa ènìyàn tàbí ó pa ènìyàn láìmọ̀-́n-mọ̀ sálọ ibẹ̀, fún ààbò lọ́wọ́ olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ ẹni ó pa. 4 Nígbà ó sálọ ̀kan nínú àwọn ìlú wọ̀nyí, yóò dúró ẹnu-ọ̀àtiwọ ibodè ìlú, ó ṣe àlàyé ara rẹ̀ iwájú àwọn àgbàgbà ìlú náà. Nígbà náà ni wọn yóò gbà á ìlú wọn, wọn yóò fun ibùgbé láàrín wọn. 5 olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ ń lépa rẹ̀, wọn gbọdọ̀ fi àwọn ̀daràn náà wọn lọ́wọ́, nítorí ó pa aládùúgbò rẹ̀ láìmọ̀, kórìíra rẹ̀ tẹ́lẹ̀ . 6 Òun ó máa gbé inú ìlú náà, títí yóò fi jẹ́jọ́ níwájú ìjọ ènìyàn àti títí ikú olórí àlùfáà ó ń ṣiṣẹ́ ìsìn nígbà náà. Nígbà náà ó padà ilé rẹ̀ ìlú ó ti ."

7 Bẹ́̀ ni wọ́n yan Kedeṣi Galili ìlú òkè Naftali, Ṣekemu ìlú òkè Efraimu, àti Kiriati-Arba (í ṣe, Hebroni) ìlú òkè Juda. 8 ìhà ìlà-oòrùn Jordani ti Jeriko, wọ́n ya Beseri aginjù pẹ̀tẹ́lẹ̀ ̀Reubeni, Ramoti Gileadi ̀Gadi, àti Golani Baṣani ̀Manase. 9 Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ọmọ Israẹli tàbí àlejò ń gbé àárín wọn ó ṣèèṣì pa ẹnìkan sálọ àwọn ìlú a sọ́tọ̀ wọ̀nyí, olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ ṣe pa á ó to di àkókò yóò jẹ́jọ́ níwájú ìjọ ènìyàn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também