Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 2

Rahabu àti àwọn Ayọ́lẹ̀

1 2.1: Hb 11.31; Jk 2.25. Nígbà náà ni Joṣua ọmọ Nuni rán àwọn ayọ́lẹ̀méjì jáde àṣírí láti Ṣittimu. Ó , "lọ wo ilẹ̀ náà, pàápàá Jeriko." Wọ́n lọ, wọ́n wọ ilé panṣágà kan, à ń Rahabu wọ́n dúró síbẹ̀.

2 A sọ fún ọba Jeriko, "ó! Àwọn ará Israẹli kan ibí alẹ́ yìí láti yọ́ ilẹ̀ ." 3 Ọba Jeriko ránṣẹ́ Rahabu , "àwọn ọkùnrin ó tọ̀ ́ , ó wọ inú ilé rẹ jáde , nítorí wọ́n láti yọ́ gbogbo ilẹ̀ yìí ni."

4 Ṣùgbọ́n obìnrin náà ti àwọn ọkùnrin méjì náà o fi wọ́n pamọ́. Ó , "Lóòtítọ́ àwọn ọkùnrin náà ̀dọ̀ mi, ṣùgbọ́n èmi mọ ibi wọ́n ti . 5 Nígbà ilẹ̀ ṣú, nígbà ó àkókò láti ti ìlẹ̀kùn ẹnu ibodè, àwọn ọkùnrin náà jáde lọ. Èmi mọ ̀wọ́n gbà lọ. lépa wọn kíákíá. ̀yin yóò wọn." 6 (Ṣùgbọ́n ó ti wọn gòkè àjà ó fi wọ́n pamọ́ abẹ́ pòròpòrò ọkà jọ orí àjà.) 7 Àwọn ọkùnrin náà jáde lọ láti lépa àwọn ayọ́lẹ̀náà ̀ó lọ ìwọdò Jordani, àwọn ń lépa wọn ti jáde, wọ́n ti ìlẹ̀kùn ẹnu ibodè.

8 àwọn ayọ́lẹ̀náà sùn alẹ́, ó gòkè tọ̀ wọ́n lọ lókè àjà. 9 Ó sọ fún wọn, "Èmi mọ̀ Olúwa ti fún un yín ilẹ̀ yìí àti ̀u yín ti sọ di ojo ibi ìdí gbogbo àwọn ó n gbé ilẹ̀ yìí ti di omi nítorí i yín. 10 Àwa ti gbọ́ Olúwa ti omi Òkun Pupa gbẹ níwájú u yín nígbà ̀yin jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, àti ohun ̀yin ṣe Sihoni àti Ogu, àwọn ọba méjèèjì ti Amori ti ìlà-oòrùn Jordani, ̀yin parun pátápátá. 11 a ti gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ọkàn wa pami okun kankan fún wa mọ́ nítorí i yín, nítorí Olúwa Ọlọ́run yín ni Ọlọ́run òkè ̀run àti ayé. 12 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, jọ̀wọ́ búra fún mi ti Olúwa ̀yin yóò ṣe àánú fún ìdílé mi, nítorí mo ti ṣe yín oore. ̀yin yóò fún mi àmì dájú: 13 ̀yin yóò ̀baba àti ìyá mi ; arákùnrin mi àti arábìnrin mi, àti ohun gbogbo wọ́n , àti ̀yin yóò gbà lọ́wọ́ ikú."

14 "̀wa fún ̀in yín!" àwọn ọkùnrin náà a lójú. "ìwọ sọ ohun àwa ń ṣe, àwa yóò fi òtítọ́ àti àánú nígbà Olúwa fún wa ilẹ̀ náà."

15 Nígbà náà ó fi okùn sọ̀ wọ́n kalẹ̀ ojú u fèrèsé, nítorí ilé ó ń gbé ara odi ìlú. 16 Ó ti sọ fún wọn , "lọ orí òkè, fi ara pamọ́ níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta àwọn ń lépa yín ba à i yín títí wọn yóò fi darí. Lẹ́yìn náà máa ̀yín lọ."

17 Àwọn arákùnrin náà sọ fún un , "ọrùn un wa ba à mọ́ kúrò nínú ìbúra ìwọ wa yìí. 18 Nígbà àwa wọ ilé è rẹ, ìwọ yóò so okùn aláwọ̀ aró yìí ojú fèrèsé èyí ìwọ fi sọ̀ kalẹ̀, ìwọ ó baba rẹ, ìyá rẹ, àwọn arákùnrin in rẹ àti gbogbo ìdílé è rẹ wọ́n inú ilé è rẹ. 19 ẹnikẹ́ni jáde ìta láti inú ilé è rẹ inú ìgboro ìlú, ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò orí ara rẹ̀; ̀bi rẹ̀ yóò lórí i rẹ̀. Fún ẹnikẹ́ni ó nínú ilé pẹ̀rẹ, ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò orí i wa ẹnikẹ́ni fi ọwọ́ kàn án. 20 Ṣùgbọ́n ìwọ sọ ohun àwa ń ṣe, àwa yóò bọ́ nínú ìbúra ìwọ wa ."

21 Ó dáhùn , "Ó dára bẹ́̀. jẹ́ ó gẹ́gẹ́ ̀yin sọ."

Ó rán wọn lọ wọ́n lọ. Ó so okùn òdòdó náà ojú fèrèsé.

22 Nígbà wọ́n kúrò, wọ́n lọ orí òkè wọ́n dúró ibẹ̀ ọjọ́ mẹ́ta, títí àwọn alépa fi wọn gbogbo ̀wọ́n padà láìrí wọn. 23 Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin méjì náà padà. Wọ́n sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, wọ odò, wọ́n ̀dọ̀ Joṣua ọmọ Nuni wọ́n sọ fún un gbogbo ohun ó ti ṣẹlẹ̀ wọn. 24 Wọ́n sọ fún Joṣua, "Nítòótọ́ ni Olúwa fi gbogbo ilẹ̀ náà wa lọ́wọ́; gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà ni ìbẹ̀rùbojo ti nítorí i wa."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também