Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 11

A ṣẹ́gun àwọn ọba ìhà àríwá

1 Nígbà Jabini ọba Hasori gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ó ránṣẹ́ Jobabu ọba Madoni, ọba Ṣimroni àti Akṣafu, 2 àti àwọn ọba ìhà àríwá wọ́n orí òkè aginjù, gúúsù ti Kinnereti, ẹsẹ̀ òkè ìwọ̀-oòrùn àti Nafoti Dori ìwọ̀-oòrùn; 3 àwọn ará Kenaani ìlà-oòrùn àti ìwọ̀-oòrùn; àwọn Amori, Hiti, Peresi àti Jebusi orí òkè; àti àwọn Hifi ìsàlẹ̀ Hermoni agbègbè Mispa. 4 Wọ́n jáde pẹ̀gbogbo ogun wọn àti ̀pọ̀lọpọ̀ ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun ńlá, wọ́n pọ̀, gẹ́gẹ́ iyanrìn etí òkun. 5 Gbogbo àwọn ọba yìí pa ọmọ-ogun wọn pọ̀, wọ́n pa ibùdó ibi omi Meromu láti Israẹli .

6 Olúwa sọ fún Joṣua , "ṣe bẹ̀wọn, nítorí àkókò yìí ̀la, gbogbo wọn ni èmi yóò fi Israẹli lọ́wọ́ pípa. Ìwọ yóò iṣan ̀yìn ẹṣin wọn, ìwọ yóò sun kẹ̀kẹ́ ogun wọn."

7 Bẹ́̀ ni Joṣua àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ yọ wọn òjijì ibi omi Meromu, wọ́n kọlù wọ́n, 8 Olúwa fi wọ́n Israẹli lọ́wọ́. Wọ́n ṣẹ́gun wọn, wọ́n lépa wọn gbogbo ̀títí Sidoni ńlá, Misrefoti-Maimu, àti àfonífojì Mispa ìlà-oòrùn, títí fi ku ẹnìkankan sílẹ̀. 9 Joṣua ṣe wọn gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ: Ó iṣan ̀yìn ẹsẹ̀ ẹṣin wọn ó sun kẹ̀kẹ́ ogun wọn.

10 àkókò náà Joṣua padà sẹ́yìn, ó ṣẹ́gun Hasori, ó fi idà pa ọba rẹ̀. (Hasori jẹ́ olú fún gbogbo àwọn ìlú wọ̀nyí di àkókò .) 11 Wọ́n fi idà pa gbogbo àwọn ènìyàn ó ibẹ̀. Wọ́n pa wọ́n run pátápátá, wọn fi ohun alààyè kan sílẹ̀; ó fi iná sun Hasori fúnra rẹ̀.

12 Joṣua gbogbo àwọn ìlú ọba àti ọba wọn, ó fi idà pa wọ́n. Ó run gbogbo wọn, gẹ́gẹ́ Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pàṣẹ. 13 Síbẹ̀ Israẹli sun ̀kankan nínú àwọn ìlú lórí òkè kéékèèké, àyàfi Hasori nìkan Joṣua sun. 14 Àwọn ará Israẹli gbogbo ìkógun àti ohun ̀sìn ti ìlú náà fún ara wọn. Wọ́n fi idà pa gbogbo ènìyàn títí wọ́n fi run wọ́n pátápátá, ẹni ó láààyè. 15 Olúwa ti pàṣẹ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ̀, bẹ́̀ Mose pàṣẹ fún Joṣua, Joṣua ṣe bẹ́̀. fi ̀kankan sílẹ̀ láìṣe nínú gbogbo ohun Olúwa pàṣẹ fún Mose.

16 Bẹ́̀ ni Joṣua gba gbogbo ilẹ̀ náà: ilẹ̀ òkè, gbogbo gúúsù, gbogbo agbègbè Goṣeni, ẹsẹ̀ òkè ti ìwọ̀-oòrùn, aginjù àti àwọn òkè àti pẹ̀tẹ́lẹ̀ Israẹli, 17 láti òkè Halaki títí òkè Seiri, Baali-Gadi àfonífojì Lebanoni ìsàlẹ̀ òkè Hermoni. Ó gbogbo ọba wọn, ó kọlù wọ́n, ó pa wọ́n. 18 Joṣua gbogbo àwọn ọba wọ̀nyí jagun ọjọ́ pípẹ́. 19 ìlú kan ó àwọn ará Israẹli ṣe àdéhùn àlàáfíà, àyàfi àwọn ará Hifi wọ́n ń gbé Gibeoni, gbogbo wọn a jagun. 20 Nítorí Olúwa fúnra rẹ̀ ó ọkàn wọn le, wọn ó Israẹli jagun, òun pa wọ́n run pátápátá, wọn ṣe ojúrere, ṣùgbọ́n ó pa wọ́n, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

21 àkókò náà ni Joṣua lọ ó run àwọn ará Anaki kúrò ilẹ̀ òkè, láti Hebroni, Debiri, àti Anabu, àti gbogbo ilẹ̀ Juda, àti kúrò gbogbo ilẹ̀ òkè Israẹli. Joṣua run gbogbo wọn pátápátá àti ìlú wọn. 22 ará Anaki kankan ó ṣẹ́ilẹ̀ Israẹli: ṣe Gasa, Gati àti Aṣdodu. 23 Bẹ́̀ Joṣua gba gbogbo ilẹ̀ náà, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose, ó fi fún Israẹli ilẹ̀ ìní gẹ́gẹ́ ìpín wọn nípa ̀wọn.

Ilẹ̀ náà sinmi ogun.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também