Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 5

Ìkọlà fún ìran tuntun Israẹli? Ìkọlà Gilgali

1 Nígbà gbogbo àwọn ọba Amori ti ìlà-oòrùn Jordani àti gbogbo àwọn ọba Kenaani ń bẹ létí òkun gbọ́ Olúwa ti Jordani gbẹ iwájú àwọn ọmọ Israẹli títí ti a fi kọjá, ọkàn wọn pami, bẹ́̀ ni wọn ìgboyà mọ́ láti dojúkọ àwọn ọmọ Israẹli.

2 Nígbà náà ni Olúwa fún Joṣua , "Fi akọ òkúta ṣe abẹ o kọ àwọn ọmọ Israẹli ilà ìgbà ̀̀kejì." 3 Bẹ́̀ ni Joṣua ṣe abẹ akọ òkúta, ó kọ àwọn ọmọ Israẹli ilà, Gibiati-Haralotu.

4 Wàyí o, ìdí Joṣua fi kọ wọ́n nílà nìyìí. Gbogbo àwọn ọkùnrin ó ti Ejibiti jáde , gbogbo àwọn ọkùnrin ogun aginjù ̀lẹ́yìn ìgbà wọ́n jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti. 5 ó tilẹ̀ jẹ́ , gbogbo àwọn ọkùnrin jáde láti Ejibiti ni a ti kọ ilà, síbẹ̀ gbogbo ènìyàn a nínú aginjù lẹ́yìn wọ́n jáde Ejibiti ni wọn kọ ilà. 6 Àwọn ará Israẹli rìn aginjù fún ogójì ọdún títí gbogbo àwọn ọkùnrin ó ogun n nígbà wọ́n kúrò ni Ejibiti fi , nítorí wọn gbọ́rọ̀ Olúwa. Nítorí Olúwa ti búra fún wọn wọn ilẹ̀ òun ṣe ìlérí fún àwọn baba wọn láti fi fun wa, ilẹ̀ ń sàn fún wàrà àti fún oyin. 7 Bẹ́̀ ni ó gbé àwọn ọmọ wọn dìde dípò wọn, àwọn wọ̀nyí ni Joṣua kọ ilà. Wọ́n aláìkọlà nítorí a ì kọ wọ́n ilà ojú ̀. 8 Lẹ́yìn ìgbà gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọ ilà tan, wọ́n dúró ibi wọ́n ibùdó títí ilà wọn fi jinná.

9 Nígbà náà Olúwa fún Joṣua , "òní ni mo ̀gàn Ejibiti kúrò orí yín." Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ ibẹ̀ Gilgali títí ó fi di òní yìí.

Àjọ ìrékọjá Gilgali

10 ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrìnlá oṣù náà, nígbà wọ́n pàgọ́ Gilgali pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko, àwọn ọmọ Israẹli ṣe ọdún àjọ ìrékọjá. 11 ọjọ́ kejì àjọ ìrékọjá, ọjọ́ náà gan an ni, wọ́n jẹ nínú àwọn ìre oko ilẹ̀ náà: àkàrà aláìwú, àti ọkà yíyan. 12 Manna náà tan ọjọ́ kejì wọ́n jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà jáde, manna kankan mọ́ fún àwọn ará Israẹli, ṣùgbọ́n ọdún náà wọ́n jẹ ìre oko ilẹ̀ Kenaani.

Odi Jeriko lulẹ̀

13 Nígbà Joṣua súnmọ́ Jeriko, ó wo òkè ó ọkùnrin kan ó dúró iwájú rẹ̀ pẹ̀idà ọwọ́ rẹ̀. Joṣua tọ̀ ́ lọ, ó bi í , "Ǹjẹ́ ìwọ fún wa tàbí fún ̀a wa?"

14 "í ṣe fún èyíkéyìí ó fèsì, ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ olórí ogun Olúwa ni mo nísinsin yìí." Nígbà náà ni Joṣua wólẹ̀ iwájú u rẹ̀ ìbẹ̀, ó bi í léèrè, "ni Olúwa í sọ fún ìránṣẹ́ rẹ̀?"

15 Olórí ogun Olúwa a lóhùn , "Bọ́ sálúbàtà rẹ kúrò ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi ìwọ dúró yìí, ilẹ̀ mímọ́ ni." Joṣua ṣe bẹ́̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também