Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 10

Òòrùn dúró jẹ́

1 báyìí Adoni-Sedeki ọba Jerusalẹmu gbọ́ Joṣua ti gba Ai, ó ti pa wọ́n pátápátá; ó ṣe Ai àti ọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ ó ti ṣe Jeriko àti ọba rẹ̀, àti àwọn ènìyàn Gibeoni ti ṣe àdéhùn àlàáfíà pẹ̀Israẹli, wọ́n ń gbé nítòsí wọn. 2 Ìbẹ̀òun àti àwọn ènìyàn rẹ̀ torí Gibeoni jẹ́ ìlú ó ṣe pàtàkì, ̀kan nínú àwọn ìlú ọba; ó tóbi ju Ai lọ, gbogbo ọkùnrin rẹ̀ ó jẹ́ jagunjagun. 3 Nítorí náà Adoni-Sedeki ọba Jerusalẹmu bẹ Hohamu ọba Hebroni, Piramu ọba Jarmatu, Jafia ọba Lakiṣi àti Debiri ọba Egloni. pe, 4 "gòkè , ràn mi lọ́wọ́ láti kọlu Gibeoni, nítorí ó ti ìrẹ́pọ̀ pẹ̀Joṣua àti àwọn ará Israẹli."

5 Àwọn ọba Amori márààrún, ọba Jerusalẹmu, Hebroni, Jarmatu, Lakiṣi àti Egloni, ara wọn jọ, wọ́n gòkè, àwọn àti gbogbo ogun wọn, wọ́n dojúkọ Gibeoni, wọ́n kọlù ú.

6 Àwọn ará Gibeoni ránṣẹ́ Joṣua ibùdó Gilgali , "ṣe fi ìránṣẹ́ yín sílẹ̀. gòkè tọ̀ kánkán gbà . ràn lọ́wọ́, nítorí gbogbo àwọn ọba Amori ń gbé orílẹ̀-èdè òkè dojú ìjà kọ ."

7 Bẹ́̀ ni Joṣua gòkè lọ láti Gilgali pẹ̀gbogbo ogun rẹ̀, àti akọni nínú àwọn ọmọ-ogun rẹ̀. 8 Olúwa sọ fún Joṣua , "ṣe bẹ̀wọn, Mo ti fi wọ́n lọ́wọ́. ẹnikẹ́ni nínú wọn ti yóò dojúkọ ́."

9 Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti wọ́de ogun gbogbo òru náà láti Gilgali, Joṣua yọ wọn lójijì. 10 Olúwa wọn dààmú níwájú àwọn Israẹli, wọ́n pa wọ́n ìpakúpa Gibeoni. Israẹli lépa wọn ̀ó lọ Beti-Horoni, ó pa wọ́n Aseka, àti Makkeda. 11 wọ́n ń iwájú Israẹli gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ ̀láti Beti-Horoni títí Aseka, Olúwa rọ yìnyín ńlá wọn láti ̀run , àwọn ó ti ipa yìnyín pọ̀ ju àwọn àwọn ará Israẹli fi idà pa lọ.

12 ọjọ́ Olúwa fi àwọn ọmọ Amori Israẹli lọ́wọ́, Joṣua sọ fún Olúwa níwájú àwọn ará Israẹli,

"Ìwọ oòrùn, dúró jẹ́́ orí Gibeoni,

Ìwọ òṣùpá, dúró jẹ́́ lórí àfonífojì Aijaloni."

13 Bẹ́̀ ni oòrùn náà dúró jẹ́́,

òṣùpá náà dúró,

títí ìlú náà fi gbẹ̀san lára àwọn ̀rẹ̀,

gẹ́gẹ́ a ti kọ́ nínú ìwé Jaṣari.

Oòrùn dúró agbede-méjì ̀run, wọ̀ ìwọ̀n odindi ọjọ́ kan. 14 ọjọ́ o dàbí rẹ̀ ṣáájú tàbí ̀yìn rẹ̀, ọjọ́ Olúwa gbọ́ ohùn ènìyàn. Dájúdájú Olúwa fún Israẹli!

15 Nígbà náà ni Joṣua àti gbogbo Israẹli padà ibùdó Gilgali.

A pa ọba Amori márùn-ún

16 báyìí àwọn ọba Amori márùn-ún ti sálọ, wọ́n fi ara pamọ́ nínú ihò àpáta kan Makkeda, 17 nígbà wọ́n sọ fún Joṣua , a ti àwọn ọba márààrún, ti ó fi ara pamọ́ nínú ihò àpáta Makkeda, 18 ó , "òkúta ńlá ẹnu ihò àpáta náà, yan àwọn ọkùnrin ibẹ̀ láti ṣọ́ . 19 Ṣùgbọ́n, ṣe dúró! lépa àwọn ̀yín, kọlù wọ́n láti ̀yìn, ṣe jẹ́ wọn ó ìlú wọn, nítorí Olúwa Ọlọ́run yín fi wọ́n yín lọ́wọ́."

20 Bẹ́̀ Joṣua àti àwọn ọmọ Israẹli pa wọ́n ìpakúpa wọ́n pa gbogbo ọmọ-ogun àwọn ọba márààrún run, àyàfi àwọn díẹ̀ wọ́n tiraka láti ìlú olódi wọn. 21 Gbogbo àwọn ọmọ-ogun padà ̀dọ̀ Joṣua ibùdó ogun Makkeda àlàáfíà, àwọn ó dábàá láti tún kọlu Israẹli.

22 Joṣua pe, "ṣí ẹnu ihò náà, àwọn ọba márààrún jáde fún mi." 23 Bẹ́̀ ni wọ́n àwọn ọba márààrún náà kúrò nínú ihò àpáta, àwọn ọba Jerusalẹmu, Hebroni, Jarmatu, Lakiṣi àti Egloni. 24 Nígbà wọ́n àwọn ọba náà tọ Joṣua , ó pe gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli, ó sọ fún àwọn olórí ọmọ-ogun ó pẹ̀rẹ̀ , "súnmọ́ , fi ẹsẹ̀ yín ọrùn àwọn ọba wọ̀nyí." Bẹ́̀ ni wọ́n iwájú, wọ́n gbé ẹsẹ̀ ọrùn wọn.

25 Joṣua sọ fún wọn , "ṣe bẹ̀, ṣe fòyà. ṣe gírí, àyà le. Báyìí ni Olúwa yóò ṣe gbogbo àwọn ̀yín, ̀yin yóò ." 26 Nígbà náà ni Joṣua kọlù wọ́n, ó pa àwọn ọba márààrún náà, ó so wọ́n rọ̀ orí igi ̀tọ̀̀tọ̀ márùn-ún, wọ́n fi wọ́n orí igi títí di ìrọ̀lẹ́.

27 Nígbà oòrùn wọ̀, Joṣua pàṣẹ, wọ́n sọ̀ wọ́n kalẹ̀ kúrò orí igi, wọ́n gbé wọn inú ihò àpáta ibi wọ́n pamọ́ . Wọ́n fi òkúta ńlá ẹnu ihò náà, ó níbẹ̀ di òní yìí.

28 ọjọ́ náà Joṣua gba Makkeda. Ó fi ojú idà kọlu ìlú náà àti ọba rẹ̀, ó run gbogbo wọn pátápátá, fi ẹnìkan sílẹ̀. Ó ṣe ọba Makkeda gẹ́gẹ́ o ti ṣe ọba Jeriko.

A ṣẹ́gun àwọn ìlú ìhà gúúsù

29 Nígbà náà Joṣua àti gbogbo Israẹli ó pẹ̀rẹ̀ kọjá láti Makkeda lọ Libina wọ́n kọlù ú. 30 Olúwa fi ìlú náà àti ọba rẹ̀ Israẹli lọ́wọ́. Ìlú náà àti gbogbo àwọn ènìyàn ibẹ̀ ni Joṣua fi idà pa. fi ẹnìkan sílẹ̀ ibẹ̀: Ó ṣe ọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ ó ti ṣe ọba Jeriko.

31 Nígbà náà ni Joṣua àti gbogbo ará Israẹli, ó pẹ̀rẹ̀ kọjá láti Libina lọ Lakiṣi; ó í, ó kọlù ú. 32 Olúwa fi Lakiṣi Israẹli lọ́wọ́, Joṣua gbà á ọjọ́ kejì. Ìlú náà àti gbogbo ènìyàn ibẹ̀ ó fi idà pa gẹ́gẹ́ ó ti ṣe Libina. 33 àkókò yìí, Horamu ọba Geseri gòkè láti ran Lakiṣi lọ́wọ́, ṣùgbọ́n Joṣua ṣẹ́gun rẹ̀ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ títí ti fi ku ẹnìkan sílẹ̀.

34 Nígbà náà ni Joṣua àti gbogbo Israẹli ó pẹ̀rẹ̀ kọjá láti Lakiṣi lọ Egloni; wọ́n í, wọ́n kọlù ú. 35 Wọ́n gbà á ọjọ́ náà, wọ́n fi ojú idà kọlù ú, wọ́n run gbogbo ènìyàn ibẹ̀ pátápátá, gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe Lakiṣi.

36 Nígbà náà ni Joṣua àti gbogbo Israẹli ṣí láti Egloni lọ Hebroni, wọ́n kọlù ú. 37 Wọ́n gba ìlú náà, wọ́n ti idà bọ̀ ́, pẹ̀ọba rẹ̀, gbogbo ìletò wọn àti gbogbo ènìyàn ibẹ̀. Wọn ẹnìkan . Gẹ́gẹ́ ti Egloni, wọ́n run un pátápátá àti gbogbo ènìyàn inú rẹ̀.

38 Nígbà náà ni Joṣua àti gbogbo Israẹli ó pẹ̀rẹ̀ padà, wọ́n kọlu Debiri. 39 Wọ́n gba ìlú náà, ọba rẹ̀ àti gbogbo ìlú wọn, wọ́n fi idà pa wọ́n. Gbogbo ènìyàn inú rẹ̀ ni wọ́n parun pátápátá. Wọn ẹnìkankan . Wọ́n ṣe Debiri àti ọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ wọn ti ṣe Libina àti ọba rẹ̀ àti Hebroni.

40 Bẹ́̀ ni Joṣua ṣẹ́gun gbogbo agbègbè náà, ìlú òkè, gúúsù, ìlú ẹsẹ̀ òkè ti ìhà ìwọ̀-oòrùn àti gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè pẹ̀gbogbo ọba, wọn ẹnìkankan . Ó pa gbogbo ohun alààyè run pátápátá, gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti pàṣẹ. 41 Joṣua ṣẹ́gun wọn láti Kadeṣi-Barnea Gasa àti láti gbogbo agbègbè Goṣeni lọ Gibeoni. 42 Gbogbo àwọn ọba wọ̀nyí àti ilẹ̀ wọn Joṣua ṣẹ́gun ìwọ́de ogun ̀̀kan, nítorí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, fún Israẹli.

43 Nígbà náà ni Joṣua padà ibùdó Gilgali pẹ̀gbogbo Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também