Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 24

Joaṣi tún ilé Olúwa ṣe

1 24.1-14: 2Ọb 11.21–12.14. Joaṣi jẹ́ ọmọ ọdún méje nígbà ó jẹ ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ogójì ọdún. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sibia ti Beerṣeba. 2 Joaṣi ṣe ohun ó dára ojú Olúwa gbogbo àkókò Jehoiada àlùfáà. 3 Jehoiada yan ìyàwó méjì fún un, ó àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin.

4 àkókò kan, Joaṣi pinnu láti tún ilé Olúwa ṣe. 5 Ó pe àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi jọ, ó fún wọn , "lọ àwọn ìlú Juda, gba owó ìtọ́láti ọwọ́ gbogbo Israẹli láti fi tún ilé Ọlọ́run yín ṣe." Ṣùgbọ́n àwọn ará Lefi ṣe é lẹ́̀kan náà.

6 Nítorí náà ọba pa á láṣẹ fún Jehoiada olórí àlùfáà ó fún un , "ni ó o béèrè lọ́wọ́ àwọn ará Lefi láti láti Juda àti Jerusalẹmu, owó orí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti fi lélẹ̀ àti nípasẹ̀ àpéjọ gbogbo Israẹli fún àgọ́ ̀?"

7 Nísinsin yìí, àwọn ọmọkùnrin obìnrin búburú ni Ataliah ti fọ́ ilé Ọlọ́run, ó ti lo àwọn nǹkan ìyàsọ́tọ̀ fún àwọn Baali.

8 Nípasẹ̀ ọba, wọn ṣe àpótí wọ́n gbé e ìta, ẹnu-ọ̀ilé Olúwa. 9 A ṣe ìkéde Juda àti Jerusalẹmu wọ́n gbọdọ̀ fún Olúwa, owó orí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti béèrè lọ́wọ́ Israẹli aginjù. 10 Gbogbo àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ènìyàn yọ̀, wọ́n un , wọ́n ń ú sínú àpótí títí ó fi kún. 11 Nígbàkígbà a gbé àpótí wọlé láti ọwọ́ àwọn ará Lefi ọwọ́ àwọn ìjòyè ọba, wọ́n pe owó ńlá níbẹ̀ àwọn akọ̀ọba àti ìjòyè olórí àlùfáà yóò láti owó rẹ̀ kúrò, wọn yóò a padà ààyè rẹ̀. Wọ́n ṣe èyí déédé, wọ́n iye owó ńlá. 12 Ọba àti Jehoiada fi fún àwọn ọkùnrin náà ó ń ṣiṣẹ́ nínú ilé Olúwa. Wọ́n fi owó gba ẹni ń fi òkúta mọ ilé àti àwọn gbẹ́nàgbẹ́láti kọ́ ilé Olúwa padà, àti àwọn òṣìṣẹ́ pẹ̀irin àti idẹ láti tún ilé Olúwa ṣe.

13 Bẹ́̀ ni àwọn ó ń ṣiṣẹ́ náà, lọ síwájú àti síwájú ọwọ́ wọn, wọ́n tún ilé Ọlọ́run dúró ipò rẹ̀, wọ́n un le. 14 Nígbà wọ́n parí rẹ̀ tán, wọ́n owó ìyókù iwájú ọba àti Jehoiada, a fi ohun èlò fún ilé Olúwa, àní ohun èlò fún ìsìn àti fún ẹbọ pẹ̀ọpọ́n, àní ohun èlò wúrà àti fàdákà. Wọ́n ń ẹbọ sísun ilé Olúwa nígbà gbogbo gbogbo ọjọ́ Jehoiada.

Ikú Jehoiada

15 Ṣùgbọ́n Jehoiada di arúgbó, ó kún fún ọjọ́, ó , ẹni àádóje ọdún ni nígbà ó . 16 Wọ́n sin ín ìlú Dafidi pẹ̀àwọn ọba, nítorí ó ṣe rere Israẹli, àti Ọlọ́run àti ilé rẹ̀.

Ìwà búburú Joaṣi

17 Lẹ́yìn ikú Jehoiada, àwọn oníṣẹ́ Juda láti fi ìforíbalẹ̀ wọn hàn ọba. Ó fèsì wọn. 18 Wọ́n pa ilé Olúwa , Ọlọ́run baba a wọn. Wọ́n ń sin àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà. Nítorí ̀ṣẹ̀ wọn yìí, ìbínú Ọlọ́run sórí Juda àti Jerusalẹmu. 19 ó ti ó , Olúwa rán àwọn wòlíì àwọn ènìyàn láti wọn padà ̀dọ̀ rẹ̀. ó tilẹ̀ jẹ́ , wọ́n jẹ́rìí nípa wọn, wọn yóò gbọ́.

20 Nígbà náà, ̀Ọlọ́run sórí Sekariah ọmọ Jehoiada wòlíì, ó dúró níwájú àwọn ènìyàn ó , "Èyí ni ohun Olúwa : ni ó ̀yin fi tẹ̀àṣẹ Olúwa? Ìwọ yóò ṣe rere. Nítorí ìwọ ti kọ Olúwa sílẹ̀, òun pẹ̀ti kọ̀ yín sílẹ̀.’ "

21 Ṣùgbọ́n wọ́n dìtẹ̀ i, àti nípa àṣẹ ọba, wọ́n sọ ́ lókùúta pa nínú àgbàlá ààfin ilé Olúwa. 22 Ọba Joaṣi rántí inú rere Jehoiada baba Sakariah ti fihàn án ṣùgbọ́n, ó pa ọmọ rẹ̀, ó ó ti ń lọ , "Olúwa ó èyí ó ́ ìṣirò."

23 24.23-26: 2Ọb 12.17,18,20,21. òpin ọdún, àwọn ọmọ-ogun Aramu yàn láti dojúkọ Joaṣi; wọ́n gbógun ti Juda àti Jerusalẹmu, wọ́n pa gbogbo àwọn aṣáájú àwọn ènìyàn. Wọ́n rán gbogbo àwọn ìkógun ọba wọn Damasku. 24 ó ti ó , àwọn ọmọ-ogun Aramu ti pẹ̀àwọn ọkùnrin díẹ̀ Olúwa fi ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ogun wọn lọ́wọ́, nítorí Juda ti kọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn sílẹ̀. Bẹ́̀ ni wọ́n ṣe ìdájọ́ Joaṣi. 25 Nígbà àwọn ará Aramu kúrò, wọ́n fi Joaṣi sílẹ̀ pẹ̀̀pọ̀ ọgbẹ́. Àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ dìtẹ̀ si fún pípa ọmọ Jehoiada àlùfáà, wọ́n pa á orí ibùsùn rẹ̀. Bẹ́̀ ó , a sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi, ṣùgbọ́n í ṣe nínú àwọn ibojì àwọn ọba.

26 Àwọn ó dìtẹ̀ jẹ́ Sabadi, ọmọ Ṣimeati arábìnrin Ammoni àti Jehosabadi ọmọ Ṣimiriti arábìnrin Moabu. 27 Àkọsílẹ̀ àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn ̀pọ̀lọpọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀, àti àkọsílẹ̀ ti ìmúpadà sípò ilé Ọlọ́run a kọ sínú ìwé ìtumọ̀ ti àwọn ọba. Amasiah ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também