Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 4

Àwọn ìpèsè fún ilé Olúwa

1 Ó ṣe pẹpẹ idẹ, ogún ìgbọ̀nwọ́ gígùn, ogún ìgbọ̀nwọ́ fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá fún gíga. 2 4.2-5: 1Ọb 7.23-26.Ó ṣe agbada dídà ńlá ó róbótó ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá láti etí kan etí èkejì ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ni gíga rẹ̀. 3 Lábẹ́ etí, àwòrán àwọn akọ màlúù yíká mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́ kan. Àwọn akọ màlúù náà ni á ̀méjì àwòrán kan pẹ̀okùn.

4 Okùn náà dúró lórí akọ màlúù méjìlá, mẹ́ta kọjú àríwá, mẹ́ta kọjú ìwọ̀-oòrùn, mẹ́ta kọjú gúúsù mẹ́ta kọjú ìlà-oòrùn. Òkun náà sinmi lórí wọn àti gbogbo ìhà ̀yìn wọn apá àárín. 5 Ó nípọn ìbú àtẹ́lẹwọ́, etí rẹ̀ dàbí etí ife ìmumi, i ìtànná lílì ó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) bati dúró.

6 4.6–5.1: 1Ọb 7.38-51. Ó ṣe ọpọ́n mẹ́wàá fún fífọ nǹkan, ó gbé márùn-ún ka ìhà gúúsù àti márùn-ún àríwá. Nínú wọn ni ó ti ń fọ àwọn nǹkan wọ́n ń fún ẹbọ sísun ṣùgbọ́n, àwọn àlùfáà ó ń lo Òkun fún fífọ nǹkan.

7 Ó ṣe ìgbé fìtílà dúró mẹ́wàá ti wúrà gẹ́gẹ́ èyí a yàn fún wọn. A gbé wọn kalẹ̀ sínú ilé Olúwa márùn un ìhà gúúsù àti márùn-ún ìhà àríwá.

8 Ó ṣé tábìlì mẹ́wàá, ó gbé wọn inú ilé Olúwa, márùn un gúúsù àti márùn-ún ìhà àríwá. Ó ṣé ọgọ́rùn-ún ọpọ́n ìbùwọ́n wúrà.

9 Ó ṣe àgbàlá àwọn àlùfáà àti ààfin ńlá àti àwọn ìlẹ̀kùn fún ààfin, ó tẹ́ àwọn ìlẹ̀kùn náà pẹ̀idẹ. 10 Ó gbé Òkun náà ka orí ìhà gúúsù ̀igun gúúsù àríwá.

11 Huramu ṣe àwọn ìkòkò pẹ̀, àti ọkọ́ àti àwọn ọpọ́n ìbùwọ́n.

Bẹ́̀ ni Huramu parí iṣẹ́ ó ti dáwọ́fún ọba Solomoni ilé Ọlọ́run.

12 Àwọn ̀wọ́n méjì;

ọpọ́n méjì ìparí ó lókè àwọn ̀wọ́n iṣẹ́;

àwọn méjì láti bo ọpọ́n méjì ìparí ń bẹ lókè àwọn ̀wọ́n;

13 irinwó (400) pomegiranate fún iṣẹ́ ̀wọ̀n méjì náà, ẹsẹ̀ méjì pomegiranate ni fún iṣẹ́ ̀wọ̀n kan, láti bo ọpọ́n rìbìtì méjì náà ó lórí àwọn òpó náà;

14 ó ṣe àgbéró ó ṣe agbada orí wọn;

15 agbada ńlá kan àti màlúù méjìlá lábẹ́ rẹ̀;

16 àwọn ìkòkò àti ̀kọ̀ àti àmúga ẹran àti gbogbo ohun èlò ó fi ara pẹ́ .

Gbogbo ohun èlò ti Huramu-Abi fi idẹ dídán ṣe fún Solomoni ọba, fún ilé Olúwa jẹ́ idẹ dídán. 17 Ọba wọ́n ilẹ̀ amọ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jordani àárín méjì Sukkoti àti Sereda. 18 Gbogbo nǹkan wọ̀nyí Solomoni ṣe iye lórí púpọ̀ a le mọ ìwọ̀n iye idẹ ó wọ́n.

19 Solomoni pẹ̀ṣe gbogbo ohun èlò ó ilé Ọlọ́run:

pẹpẹ wúrà

tábìlì èyí àkàrà ìfihàn lórí rẹ̀;

20 àwọn ̀fìtílà a fi ojúlówó wúrà ṣe pẹ̀fìtílà wọn wọn máa gẹ́gẹ́ àṣẹ iwájú ibi mímọ́ jùlọ gẹ́gẹ́ a ṣe fi lélẹ̀;

21 pẹ̀ìtànná wúrà àti fìtílà àti ̀ni ó jẹ́ kìkìdá wúrà ó gbópọn;

22 pẹ̀̀fìtílà, àti àwokòtò àti ṣíbí àti àwokòtò tùràrí àti àwọn ìlẹ̀kùn wúrà ti inú tẹmpili, àwọn ìlẹ̀kùn ibi mímọ́ Ibi Mímọ́ Jùlọ àti àwọn ìlẹ̀kùn à wọ inú gbọ̀ngàn ńlá.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também