Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 3

Solomoni kọ́ ilé Olúwa

1 3.1-13: 1Ọb 6.1-28. Nígbà náà, Solomoni bẹ̀rẹ̀ kọ́ ilé Olúwa Jerusalẹmu lórí òkè Moria, níbi Olúwa ti farahan baba a rẹ̀ Dafidi. orí ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi, ibi Dafidi pèsè. 2 Ó bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ rẹ̀ ọjọ́ kejì oṣù kejì ọdún kẹrin ìjọba rẹ̀.

3 Ìpìlẹ̀ Solomoni gbé kalẹ̀ fún kíkọ́ ilé Ọlọ́run jẹ́ ọgọ́ta gígùn ìgbọ̀nwọ́ àti ogún fífẹ̀ ìgbọ̀nwọ́. 4 Ìloro ó níwájú ilé Olúwa náà jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́ gígùn rékọjá fífẹ̀ ilé náà àti gíga rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́ gígùn rékọjá fífẹ̀ ilé náà àti gíga rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́.

Ó tẹ́ inú rẹ̀ pẹ̀kìkì wúrà. 5 Ó fi igi firi bo ilé yàrá ńlá náà ó ó pẹ̀kìkì wúrà, ó ṣe é lọ́ṣọ̀́ pẹ̀igi ̀pẹ àti àwòrán ̀wọ̀n. 6 Ó ṣe ilé Olúwa náà lọ́ṣọ̀́ pẹ̀òkúta iyebíye. Wúrà ó jẹ́ wúrà parifaimu. 7 Ó tẹ́ àjà ilé náà pẹ̀ìtí igi àti ìlẹ̀kùn ògiri àti àwọn ìlẹ̀kùn ilé Olúwa pẹ̀wúrà, ó gbẹ́ àwòrán kérúbù sára ògiri.

8 Ó kọ́ Ibi Mímọ́ Jùlọ, gígùn rẹ̀ fífẹ̀ ilé Olúwa mu, ogún ìgbọ̀nwọ́ fún gígùn, fífẹ̀ rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́, ó tẹ́ inú rẹ̀ pẹ̀ẹgbẹ̀ta (600) tálẹ́ǹtì ti wúrà dáradára. 9 Ìwọ̀n àwọn ìṣó náà jẹ́ àádọ́ta ṣékélì. Ó tẹ́ àwọn apẹ òkè pẹ̀wúrà.

10 Ibi Mímọ́ Jùlọ, ó gbẹ́ àwòrán igi kérúbù kan, ó tẹ́ wọn pẹ̀wúrà. 11 Iye ìyẹ́ apá ìbú àtẹ́lẹwọ́ lápapọ̀ ti kérúbù, jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́ ̀kan nínú ìyẹ́ apá ti kérúbù àkọ́kọ́ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún gígùn, ó farakan ògiri ilé Olúwa. Nígbà ìyẹ́ apá kejì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún gígùn ó , farakan ìyẹ́ apá kérúbù mìíràn. 12 ìjọra, ìyẹ́ apá kan ti kérúbù kejì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún gígùn, ó farakan ògiri ilé Olúwa mìíràn; ìyẹ́ apá rẹ̀ mìíràn jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn gígùn pẹ̀ó farakan ìyẹ́ apá kérúbù àkọ́kọ́. 13 Ìyẹ́ apá àwọn kérúbù wọ̀nyí gbà ogún ìgbọ̀nwọ́. Wọ́n dúró ẹsẹ̀ wọn, wọ́n kọjú yàrá pàtàkì ńlá náà.

14 3.14: Ek 26.31. Ó ṣe aṣọ títa àwọ̀ ojú ̀run, àwọ̀ àlùkò àti àwọ̀ pupa fòò àti aṣọ ̀gbọ̀ pẹ̀kérúbù a ṣe sórí i rẹ̀.

15 3.15-17: 1Ọb 7.15-21. Níwájú ilé Olúwa náà ó ṣe òpó méjì lápapọ̀ jẹ́ márùn-ún dín lógójì ìgbọ̀nwọ́ gígùn, olúkúlùkù pẹ̀olórí lórí rẹ̀ o ń wọn ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún. 16 Ó ṣe ̀wọ̀n a hun wọ inú ara wọn, ó gbé wọn orí òpó náà. Ó ṣe ọgọ́rùn-ún pomegiranate (orúkọ èso igi) ó so wọ́n mọ́ àwọn ̀wọ̀n náà 17 Ó gbe òpó náà dúró níwájú ilé Olúwa, ̀kan gúúsù, pẹ̀̀kan àríwá. Èyí ti gúúsù, ó sọ Jakini àti èyí ti àríwá, ó sọ Boasi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também