Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 33

Manase ọba Juda

1 33.1-9: 2Ọb 21.1-9. Manase jẹ́ ọmọ ọdún méjìlá nígbà ó di ọba. Ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún márùndínlọ́gọ́ta. 2 Ó ṣe búburú ojú Olúwa. Nípa títẹ̀̀iṣẹ́ ìríra ti àwọn orílẹ̀-èdè Olúwa ti jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli rìn. 3 Ó tún kọ́ àwọn ibi gíga baba rẹ̀ Hesekiah ti fọ́ túútúú. Ó gbé àwọn pẹpẹ dìde fún àwọn Baali ó ṣe àwọn ère Aṣerah. Ó foríbalẹ̀ fún gbogbo àwọn ogun ̀run ó sìn wọ́n. 4 Ó kọ́ àwọn pẹpẹ sínú ilé Olúwa èyí Olúwa ti , "Orúkọ mi yóò Jerusalẹmu títí láé." 5 Nínú ààfin méjèèje ti ilé Olúwa, ó kọ́ àwọn pẹpẹ fún gbogbo àwọn ogun ̀run 6 Ó àwọn ọmọ ara rẹ̀ ó kọjá láàrín iná àfonífojì Beni-Hinnomu, ó ń ṣe àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó ń lo àlúpàyídà, ó ń àwọn òku àti oṣó . Ó ṣe ̀pọ̀ ohun búburú ojú Olúwa láti un bínú.

7 Ó ère gbígbẹ́ ó ti gbẹ́ ó gbé e sínú ilé Olúwa, èyí Ọlọ́run ti sọ fún Dafidi àti ọmọ rẹ̀ Solomoni, "Nínú ilé Olúwa yìí àti Jerusalẹmu, mo ti yàn kúrò nínú gbogbo àwọn ̀Israẹli, èmi yóò fi orúkọ mi síbẹ̀ títí láé. 8 Èmi yóò ṣí ẹsẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli kúrò mọ́ ilẹ̀ náà èmi ti yàn fún àwọn baba ńlá yín, níwọ̀n wọ́n ṣe pẹ̀lẹ́ láti ṣe gbogbo ohun mo paláṣẹ fún wọn, gẹ́gẹ́ gbogbo òfin, àṣẹ àti àwọn ìlànà a fún yín láti ọwọ́ Mose ." 9 Ṣùgbọ́n Manase Juda àti àwọn ń gbé Jerusalẹmu yapa, àti láti ṣe búburú ju àwọn orílẹ̀-èdè lọ, àwọn Olúwa ti parun níwájú àwọn ọmọ Israẹli.

10 Olúwa Manase sọ̀rọ̀ àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kọbi ara i. 11 Bẹ́̀ ni Olúwa àwọn alákòóso ọmọ-ogun ọba Asiria láti dojúkọ wọ́n, ó Manase nígbèkùn, ó fi ìwọ̀ un imú rẹ̀, ó é pẹ̀ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ idẹ ó un lọ Babeli. 12 Nínú ìpọ́njú rẹ̀, ó ojúrere Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. Ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ gidigidi níwájú Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀. 13 Nígbà ó gbàdúrà i, inú Olúwa dùn àdúrà rẹ̀, ó tẹ́̀bẹ̀ rẹ̀; bẹ́̀ ni ó un padà Jerusalẹmu àti ìjọba rẹ̀. Nígbà náà Manase mọ̀ Olúwa ni Ọlọ́run.

14 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí, ó mọ odi kan lẹ́yìn ìlú Dafidi, ìhà ìwọ̀-oòrùn Gihoni, àfonífojì, àní àtiwọ ẹnu ibodè ẹja, ó orí òkè Ofeli ; ó mọ ́n ga sókè gidigidi, ó fi balógun sínú gbogbo ìlú olódi Juda wọ̀n-ọn-nì.

15 Ó pa gbogbo àwọn Ọlọ́run àjèjì run. Ó gbogbo àwọn ère kúrò nínú ilé Olúwa, pẹ̀gbogbo àwọn pẹpẹ ó ti kọ́ òkè ilé Olúwa àti Jerusalẹmu; ó wọn jáde kúrò nínú ìlú. 16 Nígbà náà ni ó àwọn pẹpẹ padà bọ̀ sípò. Ó ọrẹ ìdàpọ̀ àti ọrẹ-ọpẹ́ lórí rẹ̀. Ó sọ fún Juda láti sin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. 17 Àwọn ènìyàn, ko tẹ̀síwájú láti máa ẹbọ àwọn ibi gíga. Ṣùgbọ́n Olúwa Ọlọ́run wọn nìkan.

18 Àwọn iṣẹ́ yòókù ti ìjọba Manase pẹ̀àdúrà rẹ̀ Ọlọ́run rẹ̀ àti àwọn ̀rọ̀ àwọn aríran sọ i orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, nínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli. 19 Àdúrà rẹ̀ àti inú Ọlọ́run ṣe dùn àdúrà rẹ̀ àti gbogbo àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ̀ àti àìṣòótọ́, àti àwọn òpó níbi ó kọ́ àwọn ibi gíga , ó gbé àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, gbogbo rẹ̀ ni a kọ sínú ìwé ìrántí àwọn aríran. 20 33.20: 2Ọb 21.18.Manase sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín sínú ààfin rẹ̀. Amoni ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Amoni ọba Juda

21 33.21-25: 2Ọb 21.19-24. Amoni jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà ó di ọba. Ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún méjì. 22 Ó ṣe búburú ojú Olúwa, gẹ́gẹ́ baba rẹ̀ Manase ti ṣe. Amoni ẹbọ gbogbo àwọn òrìṣà Manase baba rẹ̀ ti ṣe, ó sìn wọ́n. 23 Ṣùgbọ́n í ṣe i baba rẹ̀ Manase. rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Olúwa: ṣùgbọ́n ̀ṣẹ̀ Amoni ń pọ̀ í.

24 Àwọn oníṣẹ́ Amoni dìtẹ̀ i. Wọ́n pa á ààfin rẹ̀. 25 Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà pa gbogbo àwọn wọ́n ṣọ̀tẹ̀ ọba Amoni, wọ́n Josiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também