Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 8

Àwọn iṣẹ́ Solomoni mìíràn

1 8.1-18: 1Ọb 9.10-28. Lẹ́yìn ogún ọdún lásìkò ìgbà Solomoni kọ́ ilé Olúwa àti ilé òun fúnra rẹ̀. 2 Solomoni tún ìlú Hiramu ti fi fún un kọ́, ó àwọn ọmọ Israẹli jọ níbẹ̀ wọn ó máa gbé nínú ibẹ̀. 3 Nígbà náà Solomoni lọ Hamati-Ṣoba ó borí rẹ̀. 4 Ó tún kọ́ Tadmori aginjù àti gbogbo ìlú ìṣúra ó ti kọ́ Hamati. 5 Ó tún kọ́ òkè Beti-Horoni àti ìsàlẹ̀ Beti-Horoni gẹ́gẹ́ ìlú olódi, pẹ̀ògiri àti pẹ̀ìlẹ̀kùn àti ̀ìdábùú. 6 Àti gẹ́gẹ́ Baalati àti gbogbo ìlú ìṣúra Solomoni , àti gbogbo ìlú fún kẹ̀kẹ́ rẹ̀ àti fún àwọn ẹṣin rẹ̀ ohunkóhun ó yẹ kókó Jerusalẹmu, Lebanoni àti gbogbo àyíká agbègbè ó ń darí.

7 Gbogbo àwọn ènìyàn ó kúrò láti ara àwọn ará Hiti, ará Amori, ará Peresi, ará Hifi àti ará Jebusi àwọn ènìyàn wọ̀nyí wọn í ṣe àwọn ará Israẹli, 8 èyí ni , àwọn ọmọ wọn ó sílé ilẹ̀ náà, àwọn ọmọ Israẹli parun àwọn ni Solomoni bu iṣẹ́ ìrú fún títí di òní yìí. 9 Ṣùgbọ́n Solomoni ọmọ ̀dọ̀ lára àwọn ọmọ Israẹli, wọn jẹ́ ̀gágun rẹ̀, olùdarí àwọn oníkẹ̀kẹ́ àti olùdarí kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀. 10 Wọ́n tún jẹ́ olórí aláṣẹ fún ọba Solomoni, àádọ́ta ó nígba (250) àwọn alákòóso lórí àwọn ènìyàn.

11 Solomoni gbé ọmọbìnrin Farao sókè láti ìlú Dafidi lọ ibi ó ti kọ́ fún un, nítorí ó , "Aya mi gbọdọ̀ gbé nínú ilé Dafidi ọba Israẹli nítorí ibi àpótí ̀Olúwa wọ̀, ibi mímọ́ ni."

12 Lórí pẹpẹ Olúwa ó ti kọ́ níwájú ìloro náà, Solomoni ẹbọ sísun Olúwa, 13 nípa ìlànà ojoojúmọ́ fún ẹbọ rírú a pàṣẹ láti ̀dọ̀ Mose fún ọjọ́ ìsinmi, oṣù tuntun àti lẹ́rìn mẹ́ta lọ́dún, àjọ àìwúkàrà, àjọ ̀sẹ̀ méje àti àjọ àgọ́. 14 pípamọ́ pẹ̀ìlànà baba rẹ̀ Dafidi, ó yan ipa àwọn àlùfáà fún iṣẹ́ wọn àti àwọn ọmọ Lefi láti jẹ́ adarí láti máa yin àti láti máa ṣe ìránṣẹ́ àwọn àlùfáà gẹ́gẹ́ ìlànà ojoojúmọ́. Ó tún yàn àwọn olùṣọ́nípa pípín olúkúlùkù ẹnu-ọ̀, nítorí èyí ni Dafidi ènìyàn Ọlọ́run ti paláṣẹ. 15 Wọn kúrò nínú àṣẹ ọba àwọn àlùfáà tàbí àwọn ọmọ Lefi, nínú ohunkóhun, àti pẹ̀ti ìṣúra.

16 Gbogbo iṣẹ́ Solomoni ni a gbé jáde láti ọjọ́ ìfi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa lélẹ̀ títí ó fi di ọjọ́ ìparí. Bẹ́̀ ni ilé Olúwa parí.

17 Nígbà náà ni Solomoni lọ Esioni-Geberi àti Elati Edomu létí òkun. 18 Hiramu fi ̀kọ̀ ránṣẹ́ i nípa àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn ọkùnrin ó mòye Òkun. Èyí pẹ̀àwọn ènìyàn Solomoni, lọ Ofiri wọ́n gbé àádọ́ta irinwó (450) tálẹ́ǹtì wúrà , padà èyí wọ́n tọ ọba Solomoni .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também