Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 8

Ìbọ̀rìṣà nínú ilé Olúwa

1 ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹfà ọdún kẹfà mo ṣe jókòó nílé mi pẹ̀àwọn àgbàgbà Juda níwájú mi, ọwọ́ Olúwa Olódùmarè mi níbẹ̀. 2 Nígbà mo , mo ohun kan ó jọ ènìyàn. Láti ibi ìbàdí rẹ lọ sísàlẹ̀ dàbí iná, láti ibi ìbàdí yìí sókè mọ́lẹ̀ idẹ ń kọ mọ̀. 3 Ó na ohun dàbí ọwọ́ jáde, ó fi gba mi irun orí , ̀gbé mi sókè agbede-méjì ayé àti ̀run, ó mi lọ ìran Ọlọ́run, mo lọ Jerusalẹmu, ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀òde àríwá níbi ère owú ó ń ni bínú níwájú mi. 4 kíyèsi i, ògo Ọlọ́run Israẹli níbẹ̀, gẹ́gẹ́ ìran ti mo ni pẹ̀tẹ́lẹ̀.

5 Ó sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, gbójú sókè ìhà àríwá." Èmi náà gbójú sókè ìhà àríwá mo ère ó ń ni jowú ẹnu-ọ̀ibi pẹpẹ.

6 Ó fún mi , "Ọmọ ènìyàn, ṣé o ohun wọ́n ń ṣe ohun ìríra ńlá ilé Israẹli ń ṣe, láti mi jìnnà réré ibi mímọ́ mi? Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tún àwọn ìríra ńlá tóbi èyí lọ."

7 Ó mi ẹnu-ọ̀àgbàlá. Mo ó, mo ihò kan lẹ́gbẹ̀́ ògiri. 8 Nígbà náà sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, gbẹ́ inú ògiri náà," nígbà mo gbẹ́ inú ògiri, mo ìlẹ̀kùn kan.

9 Ó fún mi , "Wọlé ìwọ ó ohun ìríra búburú wọ́n ń ṣe níbẹ̀." 10 Mo wọlé, mo àwòrán oríṣìíríṣìí ẹranko ń nílẹ̀ àti àwọn ẹranko ìríra àti gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Israẹli wọ́n sára ògiri. 11 Níwájú wọn ni àádọ́rin ọkùnrin jẹ́ àgbàgbà ilé Israẹli dúró , Jaaṣaniah ọmọ Ṣafani dúró àárín wọn. ̀kọ̀̀kan wọn àwo tùràrí lọ́wọ́, òórùn ń jáde.

12 Ó sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, ṣé o ti ohun àwọn àgbàgbà ilé Israẹli ń ṣe nínú òkùnkùn, olúkúlùkù yàrá òrìṣà rẹ̀? Wọ́n , Olúwa wa; Olúwa ti kọ̀ ilé náà sílẹ̀.’ " 13 Ó tún sọ fún mi , "Ìwọ yóò wọn wọ́n ń ṣe àwọn ohun ìríra burú bẹ́̀ lọ."

14 Ó mi ẹnu-ọ̀ilé Olúwa ìhà àríwá, mo àwọn obìnrin jókòó, wọ́n ẹnu-ọ̀ilé Olúwa ìhà àríwá, mo àwọn obìnrin jókòó, wọ́n ń ṣọ̀fọ̀ fún Tamusi. 15 Ó sọ fún mi , "Ṣé ìwọ báyìí, ọmọ ènìyàn? Ìwọ yóò tún ìríra ga èyí lọ."

16 Ó mi ibi àgbàlá ilé Olúwa, ẹnu-ọ̀tẹmpili Olúwa, láàrín ìloro àti pẹpẹ, ni ìwọ̀n ọkùnrin mẹ́̀dọ́gbọ̀n (25) , wọ́n kẹ́yìn tẹmpili Olúwa wọn kọjú ìlà-oòrùn, wọ́n ń foríbalẹ̀ fún oòrùn apá ìlà-oòrùn.

17 Ó fún mi, "Ṣé ìwọ ti èyí ọmọ ènìyàn? Ǹjẹ́ ohun kékeré ni fún ilé Juda láti ṣe àwọn ohun ìríra wọn ń ṣe níbi yìí? Ṣé o tún yẹ wọ́n fi ìwà ipá kún ilẹ̀ wọn máa mi bínú gbogbo ìgbà? wọn bi wọn ṣe n fi ̀ka wọn sínú inú wọn. 18 Nítorí náà, èmi yóò fi ìbínú wọn ; èmi i wọn bẹ́̀ ni èmi fojú àánú wọ́n. wọ́n tilẹ̀ ń pariwo mi létí, èmi fetí wọn."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também