Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 42

Àwọn yàrá fún àwọn àlùfáà

1 Lẹ́yìn náà ó mi lọ ìta gbangba ni ìhà àríwá ó mi wọ àwọn yàrá ni òdìkejì ìta gbangba ilé Ọlọ́run àti ni òdìkejì ògiri ìta apá ìhà àríwá. 2 Ilé ìlẹ̀kùn rẹ̀ kọjú àríwá jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ gígùn, ó jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ ìbú. 3 Méjèèjì ogún ìgbọ̀nwọ́ ìpín láti inú ilé ìdájọ́ àti ni ìpín ó dojúkọ iwájú ìta ìdájọ́, ̀dẹ̀dẹ̀ lókè kọjú ̀dẹ̀dẹ̀ lókè ìdọ́gba mẹ́ta. 4 iwájú àwọn ̀, yàrá nínú ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá ìbú ó jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ gígùn. Àwọn ìlẹ̀kùn wọn apá ìhà àríwá. 5 Nísinsin yìí àwọn yàrá òkè ṣe tóóró, nítorí ̀dẹ̀dẹ̀ lókè dàbí ẹni ó ààyè láti ara wọn ju láti ara àwọn yàrá ti ó ìsàlẹ̀ tàbí àárín ilé. 6 Àwọn yàrá ó àgbékà kẹta ni àwọn òpó gẹ́gẹ́ ilé ìdájọ́ ṣe ; nítorí náà wọ́n kéré ààyè ju àwọn ó ìsàlẹ̀ àti àwọn àgbékà ti àárín. 7 Ògiri kan ìta ó ṣe déédé pẹ̀àwọn yàrá àti ìta ilé ìdájọ́; a á gùn iwájú àwọn yàrá àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́. 8 Nígbà ̀wọ́ yàrá ̀gbẹ́ ó kángun ìta ilé ìdájọ́ jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn, ̀wọ́ ti ó ̀gbẹ́ ó súnmọ́ ibi mímọ́ jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ gígùn. 9 Yàrá ìsàlẹ̀ ni ẹnu-ọ̀ìhà ìlà-oòrùn gẹ́gẹ́ ̀kan ṣe wọ inú rẹ̀ láti ìta ilé ìdájọ́.

10 ìhà gúúsù lọ ìbú ògiri ìta ilé ìdájọ́ o ṣe déédé pẹ̀àgbàlá ilé Ọlọ́run, òdìkejì ògiri ìta ni àwọn yàrá náà . 11 Àti ̀ni iwájú wọn gẹ́gẹ́ ti ìrí àwọn yàrá ó ̀àríwá wọ́n ti gùn mọ bẹ́̀ ni wọ́n gbòòrò mọ àti gbogbo ìjáde wọn dàbí ìṣe wọn àti ìlẹ̀kùn wọn 12 bẹ́̀ gẹ́gẹ́ yàrá òun ti ìlẹ̀kùn wọn ̀gúúsù, ìlẹ̀kùn kan ìbẹ̀rẹ̀ ojú ̀ó ṣe déédé pẹ̀ògiri ó gùn ìhà ìlà-oòrùn ènìyàn ń gba wọ inú àwọn yàrá.

13 Ó fún mi , "Àwọn yàrá àríwá àti àwọn yàrá gúúsù, ó níwájú ibi a sọ́tọ̀ àwọn ni yàrá mímọ́, níbi àwọn àlùfáà ti ń súnmọ́ Olúwa máa jẹ́ ohun mímọ́ jùlọ; níbẹ̀ wọn o máa gbé ohun mímọ́ jùlọ , àti ọrẹ ẹbọ jíjẹ, àti ọrẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀, àti ọrẹ ẹbọ ìrékọjá; nítorí ibẹ̀ jẹ́ mímọ́. 14 Níwọ̀n ìgbà àwọn àlùfáà ti wọ aṣọ funfun ibi mímọ́, wọn gbọdọ̀ lọ ìta ilé ìdájọ́ àfi wọ́n bọ àwọn aṣọ wọ́n fi ṣiṣẹ́ ìsin sílẹ̀ ibi wọn ó, nítorí wọ́n jẹ́ mímọ́. Wọn gbọdọ̀ wọ aṣọ mìíràn wọn súnmọ́ ibi àwọn ènìyàn yòókù máa ń ."

15 Nígbà o parí nǹkan ó nínú ilé Ọlọ́run tán, o mi jáde lọ ̀ó ìhà ìlà-oòrùn, ó wọn agbègbè náà yípo: 16 Ó wọn ìhà ìlà-oòrùn pẹ̀̀pá-ìwọ̀n nǹkan; ó jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ìgbọ̀nwọ́. 17 Ó wọn ìhà àríwá; ó jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́ pẹ̀̀pá-ìwọ̀n nǹkan. 18 O wọn ìhà gúúsù; ó jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ìgbọ̀nwọ́ pẹ̀̀wíwọ̀n nǹkan. 19 Lẹ́yìn èyí ni ó padà ìhà ìwọ̀-oòrùn o wọ̀n-ọ́n: ó jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ìgbọ̀nwọ́ pẹ̀̀wíwọ̀n. 20 Báyìí ó wọ̀n-ọ́n ̀gbẹ́ mẹ́rẹ̀̀rin. Ó ògiri kan yípo rẹ̀, ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ìgbọ̀nwọ́ ìbú, àti ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ìgbọ̀nwọ́ gígùn, láti ya ibi mímọ́ sọ́tọ̀ kúrò ibi àìmọ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também