Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 23

Ọdún àwọn ọmọ Israẹli

1 23.1-44: El 23.14-17; 34.22-24; De 16.1-17. Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, o fún wọn , Ìwọ̀nyí ni àwọn àjọ̀dún a yàn, àwọn àjọ̀dún ti Olúwa èyí gbọdọ̀ kéde gẹ́gẹ́ àjọ̀dún a yàn.

Ọjọ́ ìsinmi

3 " Ọjọ́ mẹ́ni le fi ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ni ọjọ́ ìsinmi. Ọjọ́ àjọ̀dún a yàn. gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan, níbikíbi ń gbé. Ọjọ́ ìsinmi Olúwa ni.

Ọdún ìrékọjá àti àkàrà aláìwú

4 " Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọdún Olúwa yàn, àjọ̀dún a yàn gbọdọ̀ kéde lákokò wọn. 5 Àjọ ìrékọjá Olúwa bẹ̀rẹ̀ ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní. 6 ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù kìn-ín-ní, ni àjọ̀dún àkàrà àìwú Olúwa bẹ̀rẹ̀, fún ọjọ́ méje ni gbọdọ̀ fi jẹ àkàrà ìwúkàrà. 7 ọjọ́ kìn-ín-ní àpéjọ mímọ́ ó ; ́yin gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ agbára kankan nínú rẹ̀. 8 Ọjọ́ méje ni fi ọrẹ a fi iná ṣe fún Olúwa. ọjọ́ keje, pe ìpàdé àjọ mímọ́, gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan.’ "

Ọrẹ àkọ́so

9 Olúwa sọ fún Mose pe, 10 "Sọ fún àwọn ará Israẹli, o fún wọn , Nígbà ilẹ̀ èmi yóò fún yín, ń ṣe ìkórè, síírí ọkà àkọ́kọ́ kórè fún àlùfáà. 11 ó fi síírí ọkà náà níwájú Olúwa, ó le jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún yín: àlùfáà í ọjọ́ kejì ìsinmi. 12 ọjọ́ fi síírí ọkà náà, ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan láìní àbùkù ẹbọ sísun Olúwa. 13 Pẹ̀ọrẹ ọkà rẹ ó jẹ́ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n efa (èyí jẹ́ lita mẹ́rin ààbọ̀) ti ìyẹ̀fun, a fi òróró ọrẹ a fi iná ṣe fún Olúwa òórùn dídùn pẹ̀ọrẹ ohun mímu rẹ̀ í ṣe ìdámẹ́rin òsùwọ̀n hínì (èyí jẹ́ lita kan). 14 gbọdọ̀ jẹ àkàrà kankan tàbí sun ọkà tuntun títí di ọjọ́ fi ọrẹ yín fún Ọlọ́run yín. Èyí ni ìlànà ayérayé fún ìran ń bọ̀, níbikíbi ń gbé.

Ọdún àwọn ̀sẹ̀ Pentikosti

15 " ka ̀sẹ̀ méje gbangba, láti ọjọ́ kejì ọjọ́ ìsinmi, àní ọjọ́ ìdì ọkà fífì . 16 ka àádọ́ta ọjọ́ títí ọjọ́ kejì ̀sẹ̀ méjèèje, ọrẹ ọkà tuntun fún Olúwa. 17 Láti ibikíbi ń gbé, ìṣù àkàrà méjì a fi òsùwọ̀n ìdá méjì nínú mẹ́wàá efa (èyí jẹ́ lita mẹ́rin ààbọ̀) ti ìyẹ̀fun, a fi ìwúkàrà ṣe, gẹ́gẹ́ ọrẹ fífì àkọ́so Olúwa. 18 fi akọ ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀̀kan àbùkù, ọmọ màlúù kan àti àgbò méjì kún àkàrà yìí, wọn yóò jẹ́ ẹbọ sísun Olúwa, pẹ̀ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu wọn, àní ẹbọ a fi iná ṣe, olóòórùn dídùn ni Olúwa. 19 Lẹ́yìn náà fi akọ ewúrẹ́ kan ẹbọ ̀ṣẹ̀, àti ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kọ̀̀kan fún ọrẹ àlàáfíà. 20 àlùfáà fi ̀dọ́-àgùntàn méjèèjì náà níwájú Olúwa i ọrẹ fífì pẹ̀oúnjẹ àkọ́so wọn jẹ́ ọrẹ mímọ́ Olúwa fún àlùfáà. 21 ọjọ́ yìí náà ni kéde ìpàdé àjọ mímọ́: gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran ń bọ̀ níbi yówù ń gbé.

22 23.22: Le 19.9,10; De 24.20,21. " Nígbà kórè ilẹ̀ yín ṣe kórè ìkangun oko yín, tàbí padà èyí ó ṣẹ́sílẹ̀ nínú ìkórè yín. fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn tálákà àti àwọn àlejò. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ "

Ọdún ìfùnpè

23 Olúwa sọ fún Mose , 24 "Sọ fún àwọn ará Israẹli, ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù keje, ọjọ́ ìsinmi, ìpàdé àjọ mímọ́ a fi fèrè fífọn ṣe ìrántí. 25 ṣe ṣe iṣẹ́ ojúmọ́, ṣùgbọ́n ọrẹ a fi iná sun síwájú Olúwa.’ "

Ọjọ́ ètùtù

26 Olúwa sọ fún Mose , 27 "Ọjọ́ kẹwàá oṣù keje yìí ni ọjọ́ ètùtù. ni ìpàdé àjọ mímọ́, ṣẹ́ ara yín ọrẹ a fi iná ṣe fún Olúwa. 28 ṣe ṣe iṣẹ́ kankan ọjọ́ náà, torí ọjọ́ ètùtù ni, nínú èyí a ń ṣe ètùtù fún yín níwájú Olúwa Ọlọ́run yín. 29 Ẹnikẹ́ni ṣẹ́ ara rẹ̀ ọjọ́ náà ni a ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 30 Èmi yóò pa ẹnikẹ́ni ó ṣiṣẹ́kíṣẹ́ ọjọ́ náà run kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀. 31 gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan rárá. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran ń bọ̀, níbikíbi ń gbé. 32 Ọjọ́ ìsinmi ni fún un yín, gbọdọ̀ ṣẹ́ ara yín, láti ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹsànán oṣù náà, títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ ó tẹ̀e, ni fi sinmi."

Ọdún àgọ́

33 23.33-36: De 16.13-15. Olúwa sọ fún Mose , 34 "Sọ fún àwọn ará Israẹli , ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù keje ni àjọ̀dún ọdún àgọ́ ti Olúwa bẹ̀rẹ̀ ó títí di ọjọ́ méje. 35 Ọjọ́ kìn-ín-ní jẹ́ ọjọ́ ìpàdé mímọ́, gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ ojúmọ́. 36 Ọjọ́ méje ni fi ọrẹ a fi iná ṣe , ọjọ́ kẹjọ, pe ìpàdé mímọ́ ọrẹ a fi iná ṣe fún Olúwa, èyí jẹ́ ìpàdé ó gbẹ̀yìn; ṣe ṣe iṣẹ́ ojoojúmọ́.

37 (" Ìwọ̀nyí ni àwọn àjọ̀dún Olúwa ti yàn gbọdọ̀ kéde gẹ́gẹ́ i àjọ̀dún a yàn fún mímu àwọn ọrẹ a fi iná ṣe Olúwa ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà, ọrẹ ẹbọ àti ọrẹ ohun mímu, fún ọjọ́ kọ̀̀kan. 38 Àwọn ọrẹ wọ̀nyí àfikún pẹ̀àwọn ọrẹ ọjọ́ ìsinmi Olúwa, àti pẹ̀̀bùn yín àti ohunkóhun ti jẹ́ ̀jẹ́ àti gbogbo ọrẹ àtinúwá yín fún Olúwa.)

39 " Torí náà, bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù keje lẹ́yìn ìgbà ti kórè ilẹ̀ náà, ṣe àjọ̀dún yìí fún Olúwa ọjọ́ méje. Ọjọ́ kìn-ín-ní jẹ́ ọjọ́ ìsinmi, ọjọ́ kẹjọ pẹ̀si tún jẹ́ ọjọ́ ìsinmi. 40 ọjọ́ kìn-ín-ní, àṣàyàn èso láti orí igi dáradára, imọ̀ ̀pẹ, àti ̀ka igi rúwé, àti igi wílò odò, máa yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín fún ọjọ́ méje. 41 ṣe èyí àjọ̀dún Olúwa fún ọjọ́ méje lọ́dọọdún. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran ń bọ̀, ṣe é oṣù keje. 42 gbé inú àgọ́ fún ọjọ́ méje. gbogbo ọmọ bíbí Israẹli gbé nínú àgọ́. 43 àwọn ìran yín le mọ̀ mo Israẹli gbé nínú àgọ́, nígbà mo wọn jáde Ejibiti. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ "

44 Báyìí ni Mose kéde àwọn àjọ̀dún a yàn Olúwa fún àwọn ọmọ Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também