Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìṣe àwọn Aposteli 21

Jerusalẹmu

1 Lẹ́yìn àwa ti kúrò lọ́dọ̀ wọn, a ṣíkọ̀, àwa ̀wa lọ tààrà Kosi. ọjọ́ kejì a lọ Rodu, à si gba ibẹ̀ lọ Patara, 2 A ọkọ̀ ojú omi kan ń rékọjá lọ Fonisia, a wọ inú ọkọ̀ náà, a ṣíkọ̀. 3 Nígbà àwa ń wo Saipurọsi lókèèrè, a fi í ọwọ́ òsì, a fi orí ́kọ̀ le Siria, a gúnlẹ̀ ni Tire; nítorí níbẹ̀ ni ọkọ̀ yóò ẹrù sílẹ̀. 4 Nígbà a ti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn níbẹ̀, a dúró ̀dọ̀ wọn níbẹ̀ fún ọjọ́ méje: àwọn ẹni ó ti ipá ̀fún Paulu , ó ṣe lọ Jerusalẹmu. 5 Nígbà a lo ọjọ́ wọ̀nyí tan, àwa jáde, a mu ̀pọ̀n; gbogbo wọn sìn , pẹ̀àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé títí àwa fi jáde ̀yìn ìlú, nígbà àwa gúnlẹ̀ èbúté, a gbàdúrà. 6 Nígbà a ti dágbére fún ara wa, a bọ́ ọkọ̀; bẹ́̀ ni àwọn padà lọ ilé wọn.

7 Nígbà a ti parí àjò wa láti Tire, àwa Pitolemai; nígbà ti a àwọn ará, a wọn gbé ọjọ́ kan. 8 ọjọ́ kejì a lọ kúrò, a Kesarea; nígbà á wọ ilé Filipi efangelisti ó jẹ́ ̀kan nínú àwọn méje; àwa wọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀. 9 Ọkùnrin yìí ọmọbìnrin mẹ́rin, wúńdíá, wọ́n máa ń sọtẹ́lẹ̀.

10 a níbẹ̀ lọ́jọ́ púpọ̀, wòlíì kan Judea sọ̀kalẹ̀ , a ń Agabu. 11 Nígbà ó ̀dọ̀ wa, ó àmùrè Paulu, ó de ara rẹ̀ ọwọ́ àti ẹsẹ̀, ó , "Báyìí ni ̀Mímọ́ , Báyìí ni àwọn Júù ó Jerusalẹmu yóò de ọkùnrin ó àmùrè yìí, wọn ó fi í àwọn aláìkọlà lọ́wọ́.’ "

12 Nígbà a gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, àti àwa, àti àwọn ará ibẹ̀ náà bẹ̀ ́ , ó ṣe gòkè lọ Jerusalẹmu. 13 Nígbà náà ni Paulu dáhùn , "Èwo ni ̀yin ń ṣe yìí, ̀yin ń sọkún, ń àárẹ̀ ọkàn mi; nítorí èmí múra tan, í ṣe fún dídè nìkan, ṣùgbọ́n láti pẹ̀ni Jerusalẹmu, nítorí orúkọ Jesu Olúwa." 14 Nígbà a pa á ọkàn , a dákẹ́ , "Ìfẹ́ Olúwa ni ó ṣe!"

15 Lẹ́yìn ọjọ́ wọ̀nyí, a palẹ̀mọ́, a gòkè lọ Jerusalẹmu. 16 Nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn láti Kesarea wa lọ, wọ́n wa lọ ilé Munasoni ọmọ-ẹ̀yìn àtijọ́ kan ara Saipurọsi, lọ́dọ̀ ẹni àwa yóò .

Dídé Paulu Jerusalẹmu

17 Nígbà a Jerusalẹmu, àwọn arákùnrin fi ayọ̀ gbà . 18 ọjọ́ kejì, a Paulu lọ sọ́dọ̀ Jakọbu; gbogbo àwọn alàgbà níbẹ̀. 19 Nígbà ó wọn tan, ó ròyìn lẹ́sẹẹsẹ ohun gbogbo Ọlọ́run ṣe láàrín àwọn aláìkọlà nípa iṣẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀.

20 Nígbà wọ́n gbọ́, wọ́n yin Ọlọ́run lógo, wọ́n fún un , "Arákùnrin, ìwọ iye ẹgbẹẹgbẹ̀rún nínú àwọn Júù ó gbàgbọ́, gbogbo wọn ni ó ìtara fún òfin. 21 Wọ́n ti ròyìn rẹ̀ fún wọn , ìwọ ń kọ́ gbogbo àwọn Júù ó láàrín àwọn aláìkọlà , wọn kọ Mose sílẹ̀, ó ń fún wọn wọn ṣe kọ àwọn ọmọ wọn ilà mọ́, wọn ṣe rìn gẹ́gẹ́ àṣà wọn. 22 Ǹjẹ́ èwo ni ṣíṣe? Ìjọ ṣàìmá péjọpọ̀: dájúdájú wọn yóò gbọ́ , ìwọ . 23 Ǹjẹ́ èyí àwa ó fún yìí ni o ṣe, àwa ni ọkùnrin mẹ́rin wọ́n lábẹ́ ̀jẹ́. 24 Àwọn ni ìwọ , o ṣe ìwẹ̀nùmọ́ pẹ̀wọn, ó san owó láti irun orí wọn: gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ , òtítọ́ kan nínú ohun wọ́n gbọ́ ; àti , ìwọ tìkára rẹ ń rìn déédé, ìwọ ń pa òfin Mose mọ́. 25 Ṣùgbọ́n ti àwọn aláìkọlà ó gbàgbọ́, àwa kọ̀, a ti pinnu rẹ̀ , wọn pa ara wọn mọ́ kúrò nínú ohun a fi ẹbọ òrìṣà, àti ̀jẹ̀ àti ohun ìlọ́lọ́rùnpa, àti àgbèrè."

26 Nígbà náà ni Paulu àwọn ọkùnrin náà; ọjọ́ kejì ó ṣe ìwẹ̀nùmọ́ pẹ̀wọn, ó wọ inú tẹmpili lọ, láti sọ ìgbà ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ náà yóò a ó fi ọrẹ lélẹ̀ fún olúkúlùkù wọn.

A Paulu

27 Nígbà ọjọ́ méje fẹ́rẹ̀ , àwọn Júù ó ti Asia i ni tẹmpili, wọ́n gbogbo àwọn ènìyàn sókè, wọ́n nawọ́ un. 28 Wọ́n ń kígbe , "̀yin ènìyàn Israẹli, gbà . Èyí ni ọkùnrin náà ń kọ́ gbogbo ènìyàn níbi gbogbo lòdì àwọn ènìyàn, àti òfin, àti ibí yìí, àti pẹ̀ó àwọn ará Giriki sínú tẹmpili, ó ba ibi mímọ́ yìí jẹ́." 29 Nítorí wọ́n Tirofimu ará Efesu pẹ̀rẹ̀ ìlú, ẹni wọ́n ṣe Paulu sínú tẹmpili.

30 Gbogbo ìlú ìrúkèrúdò, àwọn ènìyàn súré jọ wọ́n Paulu, wọ́n wọ́ jáde kúrò nínú tẹmpili: lójúkan náà, a ti ìlẹ̀kùn. 31 wọn ti ń ̀láti pa á, ìròyìn ̀dọ̀ olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun , gbogbo Jerusalẹmu ti dàrú. 32 Lójúkan náà, ó ti àwọn ọmọ-ogun àti àwọn balógun ̀rún, ó súré sọ̀kalẹ̀ tọ̀ wọ́n lọ; nígbà wọ́n í olórí ogun àti àwọn ọmọ-ogun dẹ́kun lílù Paulu.

33 Nígbà náà ni olórí ogun súnmọ́ wọn, ó un, ó pàṣẹ a fi ̀wọ̀n méjì é; ó béèrè ẹni ó jẹ́, àti ohun ó ṣe. 34 Àwọn kan ń kígbe ohun kan, àwọn mìíràn ń kígbe ohun mìíràn nínú àwùjọ; nígbà mọ̀ ìdí pàtàkì fún ìrúkèrúdò náà, ó pàṣẹ wọ́n un lọ sínú àgọ́ àwọn ológun. 35 Nígbà ó orí àtẹ̀gùn, gbígbé ni a gbé e sókè lọ́wọ́ àwọn ọmọ-ogun nítorí ìwà ipá àwọn ènìyàn. 36 Nítorí ̀pọ̀ ènìyàn rọ́ tẹ̀e, wọ́n ń kígbe , "un kúrò!"

̀rọ̀ Paulu níwájú àwọn ènìyàn

37 wọ́n fẹ́rẹ̀ Paulu wọ inú àgọ́ àwọn ológun lọ, ó fún olórí ogun , "Èmi ha sọ̀rọ̀ ?"

Ó dáhùn , "Ìwọ mọ èdè Giriki ? 38 Ìwọ ha kọ ara Ejibiti náà, ó ṣọ̀tẹ̀ ṣáájú ọjọ́ wọ̀nyí, ti ó ti ẹgbàajì (4,000) ọkùnrin nínú àwọn í ṣe apànìyàn lẹ́yìn lọ ijù?"

39 Ṣùgbọ́n Paulu , "Júù èmi jẹ́, ará Tarsu ìlú Kilikia, í ṣe ìlú yẹpẹrẹ kan, èmi síbẹ̀ , fún mi ààyè láti àwọn ènìyàn wọ̀nyí sọ̀rọ̀!"

40 Nígbà ó fún un ààyè, Paulu dúró lórí àtẹ̀gùn, ó juwọ́ àwọn ènìyàn. Nígbà wọ́n dákẹ́ rọ́rọ́, ó wọn sọ̀rọ̀ èdè Heberu, ,

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também