Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìṣe àwọn Aposteli 27

Paulu wọ ọkọ ojú omi lọ Romu

1 a ti pinnu rẹ̀ a wọ ọkọ̀ lọ Itali, wọn fi Paulu àti àwọn òǹdè mìíràn balógun ̀rún kan lọ́wọ́, ti a ń Juliusi, ti ẹgbẹ́ ọmọ-ogun Augustu. 2 Nígbà a wọ ọkọ̀-òkun Adramittiu kan, a fẹ́ lọ àwọn ìlú ti ó létí Òkun Asia, a ṣíkọ̀: Aristarku, ará Makedonia láti Tẹsalonika pẹ̀wa.

3 ọjọ́ kejì, a gúnlẹ̀ Sidoni. Juliusi ṣe inú rere Paulu, ó fún un láààyè ó máa tọ àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ lọ wọn le ṣe ìtọ́rẹ̀. 4 Nígbà a kúrò níbẹ̀, a lọ lẹ́bàá Saipurọsi, nítorí afẹ́fẹ́ ṣọwọ́ òdì. 5 Nígbà a Òkun Kilikia àti Pamfilia kọjá, a gúnlẹ̀ Mira ti Likia. 6 Níbẹ̀ ni balógun ̀rún ọkọ̀-òkun Alekisandiria kan, ti ń lọ Itali; ó fi wa sínú rẹ̀. 7 Nígbà a ń lọ jẹ́jẹ́ ọjọ́ púpọ̀, ti a fi agbára káká ̀kánkán Knidu, àti nítorí afẹ́fẹ́ fún wa láààyè, a ba ̀Krete lọ, lọ́kankán Salmoni. 8 Nígbà a fi agbára káká kọjá rẹ̀, a ibi a ń Èbùté Yíyanjú, ó súnmọ́ ìlú Lasea.

9 Nígbà ti a ti sọ ọjọ́ púpọ̀ , àti ìrìnàjò wa ti léwu gan an nítorí nísinsin yìí àwẹ̀ ti kọjá lọ, Paulu ìmọ̀ràn. 10 Ó fún wọn , "Alàgbà, mo wòye ìṣíkọ̀ yìí yóò ewu, òfò púpọ̀ yóò , í ṣe kìkì ti ẹrù àti ti ọkọ̀, ṣùgbọ́n ti ọkàn wa pẹ̀." 11 Ṣùgbọ́n balógun ̀rún gba ti olórí ọkọ̀ àti ti ọlọ́kọ̀ gbọ́, ju ohun wọ̀nyí Paulu lọ. 12 Àti nítorí èbúté náà rọrùn láti lo àkókò òtútù níbẹ̀, àwọn púpọ̀ dámọ̀ràn , a lọ kúrò níbẹ̀, bóyá wọn ó làkàkà Fonike, i ṣe èbúté Krete ti ó kọjú òsì ìwọ̀-oòrùn, àti ̀tún ìwọ̀-oòrùn, láti lo àkókò òtútù níbẹ̀.

Ìjì ojú omi

13 Nígbà afẹ́fẹ́ gúúsù ń fẹ́ jẹ́jẹ́, wọn ṣe ọwọ́ àwọn tẹ ohun wọn ń , wọ́n ṣíkọ̀, wọn ń gba ̀Krete lọ. 14 pẹ́ lẹ́yìn náà ni ìjì ti a ń ni Eurakuilo fẹ́ erékùṣù náà. 15 Nígbà ti ó ti gbé ọkọ̀-òkun náà, ti dojúkọ ìjì yìí, a fi i sílẹ̀, ó ń gbá a lọ. 16 Nígbà ó gbá a lọ lábẹ́ erékùṣù kan a ń Kauda, ó di iṣẹ́ púpọ̀ a súnmọ́ ìgbàjá ààbò. 17 Nígbà wọ́n gbé e sókè, wọn sa agbára láti ọkọ̀-òkun náà nísàlẹ̀, nítorí wọ́n ń bẹ̀á máa ba à gbé wọn sórí iyanrìn dídẹ̀, wọn fi ìgbokùn sílẹ̀, bẹ́̀ ni a ń gbá wa kiri. 18 a ti ń ṣe làálàá gidigidi nínú ìjì náà, ni ọjọ́ kejì wọn ẹrù-ọkọ̀ omi láti ọkọ̀ fẹ́rẹ̀. 19 ọjọ́ kẹta, wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ohun èlò ọkọ̀ dànù. 20 Nígbà oòrùn àti ìràwọ̀ si hàn lọ́jọ́ púpọ̀, ìjì náà mọ níwọ̀n fún wa, àbá àti fún wa mọ́.

21 Nígbà wọ́n àìjẹun lọ́jọ́ púpọ̀, nígbà náà Paulu dìde láàrín wọn, o , "Alàgbà, ̀yin ti gbọ́ tèmi a ṣe ṣíkọ̀ kúrò Krete, ewu àti òfò yìí ìbá ti wa. 22 Ǹjẹ́ nísinsin yìí gbà yín níyànjú, tújúká; nítorí yóò òfò ̀nínú yín, ṣe ti ọkọ̀. 23 Nítorí angẹli Ọlọ́run, ẹni èmi jẹ́ tirẹ̀, àti ẹni ti èmi ń sìn, ó dúró mi ni òru àná. 24 Ó , bẹ̀, Paulu; ìwọ ṣàìmá dúró níwájú Kesari. ó, Ọlọ́run ti fi gbogbo àwọn ti ó wọ ọkọ̀ pọ̀ fún .25 Ǹjẹ́ nítorí náà, alàgbà, dárayá: nítorí mo gba Ọlọ́run gbọ́ , yóò bẹ́̀ gẹ́gẹ́ a ti sọ fún mi. 26 Ṣùgbọ́n a ó gbá wa erékùṣù kan."

Rírì ọkọ̀

27 Ṣùgbọ́n nígbà ó di òru ọjọ́ kẹrìnlá, a ti ń gbé wa kọjá lọ láàrín Òkun Adria, láàrín ̀gànjọ́ àwọn atukọ̀ funra , àwọn súnmọ́ etí ilẹ̀ kan. 28 Nígbà wọ́n wọn Òkun, wọ́n i ó ogún ìgbọ̀nwọ́, nígbà í wọ́n sún síwájú díẹ̀, wọ́n tún wọn Òkun, wọn i ó ni ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dógún. 29 Nígbà wọ́n bẹ̀wọn ṣe rọ́ lu orí òkúta, wọ́n sọ ìdákọ̀mẹ́rin sílẹ̀ ni ìdí ọkọ̀, wọ́n ń retí ojúmọ́. 30 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn atukọ̀ ń ̀láti kúrò nínú ọkọ̀, wọ́n ti sọ àwọn ọkọ̀ kéékèèké kalẹ̀ ojú Òkun, ẹni wọn ń fẹ́ sọ ìdákọ̀sílẹ̀ níwájú ọkọ̀. 31 Paulu fún balógun ̀rún àti fún àwọn ọmọ-ogun , "ṣe àwọn wọ̀nyí dúró nínú ọkọ̀ ̀yin yóò !" 32 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ogun okùn àwọn ọkọ̀ kéékèèké, wọ́n ú sílẹ̀ ó ṣubú sọ́hùn-ún.

33 Nígbà ilẹ̀ ń mọ́ bọ̀, Paulu bẹ gbogbo wọn wọn jẹun díẹ̀, ó , "Òní ni ó di ìjẹrìnlá ̀yin ti ń retí, ti dẹ́kun gbígbààwẹ̀, jẹun. 34 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, jẹun díẹ̀, nítorí èyí ni fún ìgbàlà yín: nítorí irun kan yóò kúrò lórí ẹnìkan nínú yín." 35 Nígbà ó nǹkan wọ̀nyí, ó àkàrà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run níwájú gbogbo wọn: nígbà ó si ú, ó bẹ̀rẹ̀ i jẹ. 36 Nígbà náà ni gbogbo wọ́n dárayá, àwọn pẹ̀gba oúnjẹ. 37 Gbogbo wa ń bẹ nínú ọkọ̀-òkun náà jẹ́ ̀rìnlúgba ènìyàn ó dín mẹ́rin (276). 38 Nígbà wọn jẹun tan, wọn bẹ̀rẹ̀ mu ọkọ̀-òkun náà fúyẹ́, nípa kíkó alikama omi.

39 Nígbà ilẹ̀ mọ́, wọn mọ́ ilẹ̀ náà; ṣùgbọ́n wọn apá odò kan ó èbúté, níbẹ̀ ni wọ́n gbèrò, bóyá ó le ṣe é ṣe láti mu ọkọ̀ gúnlẹ̀. 40 Nígbà wọ́n ìdákọ̀kúrò, wọn wọn sínú Òkun, lẹ́sẹ̀kan náà wọn ìdè-ọkọ̀, wọn ta ìgbokùn iwájú ọkọ̀ afẹ́fẹ́, wọn wakọ̀ kọjú etí Òkun. 41 Nígbà wọ́n ibi Òkun méjì pàdé, wọn fi orí ọkọ̀ sọlẹ̀: iwájú rẹ̀ kàn mọ́lẹ̀ ṣinṣin, ó dúró, , ṣùgbọ́n agbára rírú omi bẹ̀rẹ̀ fọ́ ìdí ọkọ̀ náà.

42 Èrò àwọn ọmọ-ogun ni ki a pa àwọn òǹdè, ẹnikẹ́ni wọn ba à wẹ̀ jáde sálọ. 43 Ṣùgbọ́n balógun ̀rún ń fẹ́ gba Paulu , ó kọ èrò wọn, ó pàṣẹ fún àwọn ó wẹ̀ wọn bọ́ Òkun lọ ilẹ̀. 44 Àti àwọn ìyókù, òmíràn lórí pátákó, àti òmíràn lórí àwọn igi ó ya kúrò lára ọkọ̀. Bẹ́̀ ni ó ṣe gbogbo wọn yọ, àlàáfíà ilẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também