Pular para o conteúdo
Publicidade

Ìṣe àwọn Aposteli 11

Peteru ṣàlàyé nípa àwọn ìhùwàsí rẹ̀

1 Àwọn aposteli àti àwọn arákùnrin ti ó ni Judea gbọ́ àwọn aláìkọlà pẹ̀ti gba ̀rọ̀ Ọlọ́run. 2 Nígbà Peteru gòkè Jerusalẹmu, àwọn ti ìkọlà ń a wíjọ́ 3 , "Ìwọ wọlé tọ àwọn ènìyàn aláìkọlà lọ, ó wọn jẹun."

4 11.4-17: Ap 10.1-48. Ṣùgbọ́n Peteru bẹ̀rẹ̀ á wọn lẹ́sẹẹsẹ, , 5 "Èmi ni ìlú Joppa, mo ń gbàdúrà, mo ìran kan lójúran. Ohun èlò kan sọ̀kalẹ̀ ewé tákàdá ńlá, a ti igun mẹ́rẹ̀̀rin rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ láti ̀run ; ó títí de ̀dọ̀ mi. 6 Mo tẹjúmọ́ ọn, mo fiyèsí i, mo ẹran ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin, àti ẹranko igbó, àti ohun ń rákò, àti ẹyẹ ojú ̀run. 7 Mo gbọ́ ohùn kan ti ó fọ̀ mi , Dìde, Peteru: máa pa, ó máa jẹ.

8 "Ṣùgbọ́n mo dáhùn , Rara Olúwa! Nítorí ohun èèwọ̀ tàbí ohun aláìmọ́ kan wọ ẹnu mi láéláé.

9 "Ṣùgbọ́n ohùn kan dáhùn nígbà ̀̀kejì láti ̀run , Ohun Ọlọ́run ti wẹ̀mọ́, ìwọ ṣe é àìmọ́.’ 10 Èyí ṣẹlẹ̀ nígbà mẹ́ta; a tún fa gbogbo rẹ̀ sókè ̀run.

11 "ó, lójúkan náà ọkùnrin mẹ́ta dúró níwájú ilé ti a gbé , ti a rán láti Kesarea mi. 12 ̀fún mi , èmi wọn lọ, ki èmi ṣe kọminú ohunkóhun. Àwọn arákùnrin mẹ́wọ̀nyí mi lọ, a wọ ilé ọkùnrin náà. 13 Ó sọ fún wa òun ti angẹli kan ó dúró ilé rẹ̀, ó , Ránṣẹ́ lọ Joppa, ó pe Simoni àpèlé rẹ̀ jẹ́ Peteru; 14 ẹni yóò sọ ̀rọ̀ fún , nípa èyí a ó fi gba ìwọ àti gbogbo ilé rẹ .

15 "mo ti bẹ̀rẹ̀ sọ, ̀Mímọ́ wọn, gẹ́gẹ́ ó ti wa ni àtètèkọ́ṣe. 16 11.16: Ap 1.5.Nígbà náà ni mo rántí ̀rọ̀ Olúwa, ó ti , Johanu fi omi bamitiisi nítòótọ́; ṣùgbọ́n a ó fi ̀Mímọ́ bamitiisi yín. 17 Ǹjẹ́ Ọlọ́run ti fi irú ̀bùn kan náà fún wọn ó ti fi fún àwa pẹ̀nígbà a gba Jesu Kristi Olúwa gbọ́, ta ni èmi n ó fi mo le è de Ọlọ́run ̀?"

18 Nígbà wọ́n gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, wọ́n pa ẹnu wọn mọ́, wọ́n yin Ọlọ́run ògo , "Ǹjẹ́ Ọlọ́run fi ìrònúpìwàdà ìyè fún àwọn aláìkọlà pẹ̀!"

Ìjọ Antioku

19 11.19: Ap 8.4. Nítorí náà àwọn a túká kiri nípasẹ̀ inúnibíni ó dìde ti Stefanu, wọ́n rìn títí de Fonisia, àti Saipurọsi, àti Antioku, wọn sọ ̀rọ̀ náà fún ẹnìkan ṣe fún kìkì àwọn Júù. 20 Ṣùgbọ́n àwọn kan ń bẹ nínú wọn ó jẹ́ ará Saipurọsi àti Kirene; nígbà wọ́n Antioku, wọ́n sọ̀rọ̀ fún àwọn Helleni pẹ̀, wọ́n ń wàásù ìròyìn ayọ̀ nípa Jesu Olúwa. 21 Ọwọ́ Olúwa pẹ̀wọn, ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn gbàgbọ́, wọ́n yípadà Olúwa.

22 Ìròyìn nípa wọn etí ìjọ ti ó ni Jerusalẹmu; wọ́n rán Barnaba lọ títí Antioku; 23 Nígbà ti ó ti ó ̀oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run, ó yọ̀, ó gba gbogbo wọn níyànjú , pẹ̀ìpinnu ọkàn ni wọn fi ara mọ́ Olúwa. 24 Nítorí òun jẹ́ ènìyàn rere, ó kún fún ̀Mímọ́ àti fún ìgbàgbọ́; ènìyàn púpọ̀ ni a kún Olúwa.

25 Barnaba jáde lọ Tarsu láti Saulu, 26 nígbà ó i, ó un Antioku. Fún ọdún kan gbáko ni wọ́n fi ń ìjọ péjọpọ̀, wọ́n kọ́ ènìyàn púpọ̀. Antioku ni a kọ́kọ́ ti pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ni "Kristiani."

27 ọjọ́ wọ̀nyí ni àwọn wòlíì ti Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ Antioku. 28 Nígbà ̀kan nínú wọn, ti a ń ni Agabu dìde, ó ti ipa ̀sọ , ìyàn ńlá yóò yíká gbogbo ilẹ̀ Romu. (Èyí ṣẹlẹ̀ nígbà ìṣèjọba Kilaudiu.) 29 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pinnu, olúkúlùkù gẹ́gẹ́ agbára rẹ̀ ti , láti rán ìrànlọ́wọ́ àwọn arákùnrin ó Judea. 30 Wọn ṣe bẹ́̀, wọn fi ̀bùn ránṣẹ́ àwọn àgbà láti ọwọ́ Barnaba àti Saulu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também