Pular para o conteúdo
Publicidade

Heberu 6

1 Nítorí náà, ó yẹ á fi àwọn ̀kọ́ ìgbà a ṣẹ̀ṣẹ̀ gba Kristi sílẹ̀, á tẹ̀síwájú nínú àwọn ̀kọ́ yóò wa dàgbàsókè pípé. Láìtún ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ máa tẹnumọ́ ̀kọ́ ìpìlẹ̀ i ìrònúpìwàdà kúrò nínú òkú iṣẹ́ àti ìgbàgbọ́ nípa ti Ọlọ́run, 2 ti ̀kọ́ àwọn bamitiisi, àti ti ìgbọ́wọ́-léni, ti àjíǹde òkú, àti ìdájọ́ àìnípẹ̀kun. 3 Èyí àwa yóò ṣe Ọlọ́run fẹ́.

4 Nítorí , ṣe é ṣe fún àwọn a ti lójú lẹ́̀kan, wọ́n ti tọ́ ̀bùn ̀run , wọn ti di alábápín ̀Mímọ́, 5 wọn tọ́ ̀rọ̀ rere Ọlọ́run , àti agbára ayé ń bọ̀, 6 láti tún sọ wọ́n di ̀tun ìrònúpìwàdà wọn ṣubú kúrò; nítorí wọ́n tún kan Ọmọ Ọlọ́run mọ́ àgbélébùú ara wọn lọ́tun, wọ́n dójútì í gbangba. 7 Nítorí ilẹ̀ ó ń fa omi òjò ń rọ̀ sórí rẹ̀ nígbà gbogbo mu, ó ń hu ewébẹ̀ ó dára fún àwọn à ń tìtorí wọn ro ó pẹ̀, ń gba ìbùkún lọ́wọ́ Ọlọ́run. 8 6.8: Gẹ 3.17-18.Ṣùgbọ́n ó ba ń hu ̀gún àti òṣùṣú yóò di kíkọ̀sílẹ̀, si jìnnà fífi gégùn ún, òpin èyí yóò fún ìjóná.

9 Ṣùgbọ́n olùfẹ́, àwa ohun ó dára bẹ́̀ lọ, tiyín, àti ohun ó fi ara mọ́ ìgbàlà, ó tilẹ̀ jẹ́ à ń ṣe báyìí sọ̀rọ̀. 10 Nítorí Ọlọ́run í ṣe aláìṣòdodo yóò fi gbàgbé iṣẹ́ yin àti ìfẹ́ ̀yin fihàn orúkọ rẹ̀, nípa iṣẹ́ ìránṣẹ́ ti ṣe fún àwọn ènìyàn mímọ́, tún ń ṣe. 11 Àwa fẹ́ olúkúlùkù yín máa fi irú àìsimi kan náà hàn, fún ̀kún ìdánilójú ìrètí títí òpin. 12 ṣe di onílọ̀ra, ṣùgbọ́n aláfarawé àwọn wọn ti ipa ìgbàgbọ́ àti sùúrù jogún àwọn ìlérí.

Ìdánilójú ìlérí Ọlọ́run

13 6.13-14: Gẹ 22.16-17. Nítorí nígbà Ọlọ́run ṣe ìlérí fún Abrahamu, ti ẹni ó pọ̀òun láti fi búra, ó fi ara rẹ̀ búra, , 14 "Nítòótọ́ bíbùkún èmi ó bùkún fún , àti bíbísí èmi ó i." 15 Bẹ́̀ náà ni, lẹ́yìn ìgbà Abrahamu fi sùúrù dúró, ó ri ìlérí náà gbà.

16 Nítorí ènìyàn a máa fi ẹni ó pọ̀wọ́n lọ búra: ìbúra náà a fi òpin gbogbo ìjiyàn wọn fún ìfẹ̀sẹ̀ múlẹ̀ ̀rọ̀. 17 Nínú èyí Ọlọ́run, ẹni ń fẹ́ gidigidi láti fi àìlèyípadà ète rẹ̀ hàn fún àwọn ajogún ìlérí náà, ó fi ìbúra sáàrín wọn. 18 , nípa ohun àìlèyípadà méjì, nínú èyí le ṣe é ṣe fún Ọlọ́run láti ṣèké, a àwa ó ti sábẹ́ ààbò rẹ̀ ọkàn láti di ìrètí a gbé kalẹ̀ níwájú wa ṣinṣin. 19 6.19: Le 16.2.Èyí àwa níbi ìdákọ̀ọkàn fún ọkàn wa, ìrètí ó dájú ó dúró ṣinṣin, ó wọ inú ilé lọ lẹ́yìn aṣọ ìkélé; 20 6.20: Sm 110.4.níbi Jesu, aṣáájú wa ti wọ̀ lọ fún wa, òun ni a fi jẹ alábojútó àlùfáà títí láé ipasẹ̀ Melkisedeki.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também