Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 17

Ahitofeli gbìmọ̀ a lépa Dafidi

1 Ahitofeli fún Absalomu , "Èmi ó yan ẹgbàá mẹ́(12,000) ọkùnrin èmi ó dìde, èmi ó lépa Dafidi lóru yìí. 2 Èmi ó yọ i nígbà àárẹ̀ un ọwọ́ rẹ̀ ṣe aláìle, èmi ó a ìjì, gbogbo àwọn ènìyàn ó lọ́dọ̀ rẹ̀ yóò , èmi ó kọlu ọba nìkan ṣoṣo. 3 Èmi ó gbogbo àwọn ènìyàn padà sọ́dọ̀ rẹ bi ìgbà ìyàwó padà ̀dọ̀ ọkọ rẹ̀. Ọkàn ẹnìkan ṣoṣo ìwọ ń yìí ni ó túmọ̀ ìpadàbọ̀ gbogbo wọn; gbogbo àwọn ènìyàn yóò àlàáfíà." 4 ̀rọ̀ náà tọ́ lójú Absalomu, àti lójú gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli.

Huṣai fi ọgbọ́n ìmọ̀ náà po

5 Absalomu , "Ǹjẹ́ pe Huṣai ará Arki, àwa ó gbọ́ èyí ó lẹ́nu rẹ̀ pẹ̀." 6 Huṣai ̀dọ̀ Absalomu, Absalomu fún un , "Báyìí ni Ahitofeli , àwa ṣe ̀rọ̀ rẹ ? ko tọ́ bẹ́̀, ìwọ ."

7 Huṣai fún Absalomu , "Ìmọ̀ Ahitofeli gbà yìí, dára nísinsin yìí." 8 Huṣai , "Ìwọ mọ baba rẹ àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ alágbára ni wọ́n, wọ́n kíkorò ọkàn àmọ̀tẹ́kùn a gbà ọmọ ni pápá, baba rẹ jẹ́ jagunjagun ọkùnrin yóò àwọn ènìyàn náà gbé pọ̀ lóru. 9 Kíyèsi i, ó ti fi ara rẹ̀ pamọ́ nísinsin yìí ni ihò kan, tàbí ibòmíràn: yóò ṣe, nígbà díẹ̀ nínú wọn kọ́ ṣubú, ẹnikẹ́ni ó gbọ́ yóò , Ìparun ń bẹ́ nínú àwọn ènìyàn ń tọ Absalomu lẹ́yìn.10 Ẹni ó ṣe alágbára, ọkàn rẹ̀ dàbí ọkàn kìnnìún, yóò rẹ̀ ́: nítorí gbogbo Israẹli ti mọ̀ alágbára ni baba rẹ, àti , àwọn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ jẹ́ alágbára.

11 "Nítorí náà èmi dámọ̀ràn , gbogbo Israẹli wọ́jọ pọ̀ sọ́dọ̀ rẹ, láti Dani títí Beerṣeba, gẹ́gẹ́ iyanrìn létí òkun fún ̀pọ̀lọpọ̀; àti , ìwọ tìkára rẹ̀ ó lọ ogun náà. 12 Àwa ó yọ i níbikíbi àwa o gbé i, àwa ó i ìrì ti ń ṣẹ̀ ilẹ̀ àní, ọkàn kan yóò pẹ̀rẹ̀ nínú gbogbo àwọn ọmọkùnrin ó lọ́dọ̀ rẹ̀. 13 o bọ́ ìlú kan, gbogbo Israẹli yóò okùn ìlú náà, àwa ó á lọ odò, títí a yóò fi òkúta kéékèèké kan níbẹ̀."

14 Absalomu àti gbogbo ọkùnrin Israẹli , "Ìmọ̀ Huṣai ará Arki sàn ju ìmọ̀ Ahitofeli lọ! Nítorí Olúwa fẹ́ láti ìmọ̀ rere ti Ahitofeli po." Nítorí Olúwa ibi sórí Absalomu.

Huṣai ránṣẹ́ Dafidi nípa ìmọ̀ náà

15 Huṣai fún Sadoku àti fún Abiatari àwọn àlùfáà , "Báyìí ni Ahitofeli ti Absalomu àti àwọn àgbàgbà Israẹli dámọ̀ràn, báyìí lèmi a dámọ̀ràn. 16 Nítorí náà yára ránṣẹ́ nísinsin yìí o sọ fún Dafidi , ṣe dúró pẹ̀tẹ́lẹ̀ ijù náà lálẹ́ yìí, ṣùgbọ́n yára rékọjá a a gbé ọba , àti gbogbo àwọn ènìyàn ó ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ.’ "

17 Jonatani àti Ahimasi dúró En-Rogeli ̀dọ́mọdébìnrin kan lọ, ó sọ fún wọn, wọ́n lọ wọ́n sọ fún Dafidi ọba nítorí a à wọn wọ́n wọ ìlú. 18 Ṣùgbọ́n ̀dọ́mọdékùnrin kan wọn, ó fún Absalomu, ṣùgbọ́n àwọn méjèèjì yára lọ kúrò, wọ́n ilé ọkùnrin kan Bahurimu, ẹni ó kànga kan ọgbà rẹ̀, wọ́n sọ̀kalẹ̀ ibẹ̀. 19 Obìnrin rẹ̀ nǹkan ó fi bo kànga náà, ó àgbàdo sórí rẹ̀, a mọ̀.

20 Àwọn ìránṣẹ́ Absalomu tọ obìnrin náà ilé náà, wọ́n béèrè , "Níbo ni Ahimasi àti Jonatani gbé ?"

Obìnrin náà fún wọn , "Wọ́n ti gòkè rékọjá ìṣàn odò náà." Wọ́n wọn kiri, wọn wọn, wọ́n yípadà Jerusalẹmu.

21 Ó ṣe lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti lọ tán, àwọn ọkùnrin náà jáde kúrò nínú kànga, wọ́n lọ wọ́n fún Dafidi ọba. Wọ́n sọ fún Dafidi , "Dìde o gòkè odò kánkán, nítorí báyìí ni Ahitofeli gbìmọ̀ ." 22 Dafidi dìde, àti gbogbo àwọn ènìyàn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n gòkè odò Jordani: ilẹ̀ mọ́, ènìyàn gòkè odò Jordani.

Ahitofeli pokùnso

23 Nígbà Ahitofeli i wọn fi ìmọ̀ tirẹ̀ ṣe, ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ni gàárì, ó dìde, ó lọ ilé rẹ̀, ó palẹ̀ ilé rẹ̀ mọ̀, ó so, ó , a sin ín ibojì baba rẹ̀. Absalomu gbógun ti Dafidi.

24 Dafidi Mahanaimu, Absalomu gòkè odò Jordani, òun àti gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli pẹ̀rẹ̀. 25 Absalomu fi Amasa ṣe olórí ogun ipò Joabu: Amasa ẹni í ṣe ọmọ ẹnìkan, orúkọ ẹni a ń Itira, ará Israẹli, ó wọlé tọ Abigaili ọmọbìnrin Nahaṣi, arábìnrin Seruiah, ìyá Joabu. 26 Israẹli àti Absalomu ilẹ̀ Gileadi.

27 Nígbà Dafidi Mahanaimu, Ṣobi ọmọ Nahaṣi ti Rabba àwọn ọmọ Ammoni, àti Makiri ọmọ Ammieli ti Lo-Debari, àti Barsillai ará Gileadi ti Rogelimu. 28 àwọn àkéte, àti àwọn àwo, àti ìkòkò amọ̀, àti alikama, àti ọkà barle, àti ìyẹ̀fun, àti àgbàdo díndín, àti ̀, àti erèé, àti lẹntili. 29 Àti oyin, àti òrí-àmọ́, àti àgùntàn, àti wàràǹkàṣì màlúù, fún Dafidi àti fún àwọn ènìyàn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀, láti jẹ: nítorí wọ́n , "Ebi ń pa àwọn ènìyàn, ó rẹ̀ wọ́n, òǹgbẹ ń gbẹ wọ́n aginjù."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também