Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 21

Ọlọ́run kọ ìbéèrè Sedekiah sílẹ̀

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah nígbà ọba Sedekiah rán Paṣuri ọmọ Malkiah àti àlùfáà Sefaniah ọmọ Maaseiah i; wọ́n : 2 "Wádìí lọ́wọ́ Olúwa fún wa nítorí Nebukadnessari ọba Babeli ń kọlù . Bóyá Olúwa yóò ṣe ìyanu fún wa gẹ́gẹ́ ti àtẹ̀yìnwá, ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa."

3 Ṣùgbọ́n Jeremiah dáhùn , "Sọ fún Sedekiah, 4 Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli , Èmi fẹ́ kọjú idà ó lọ́wọ́ yín yín, èyí ̀ ń láti ọba àti àwọn ará Babeli wọ́n lẹ́yìn odi , Èmi yóò wọn jọ sínú ìlú yìí. 5 Èmi gan an yóò yín pẹ̀ohun ìjà olóró nínú ìbínú àti ìrunú líle. 6 Èmi yóò lu gbogbo ìlú yìí, ènìyàn àti ẹranko, gbogbo wọn ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò kọlù wọn yóò . 7 Olúwa sọ lẹ́yìn èyí, èmi yóò fi Sedekiah ọba Juda, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àti àwọn ènìyàn, àti àwọn ó ìlú yìí lọ́wọ́ àjàkálẹ̀-ààrùn àti lọ́wọ́ idà, àti lọ́wọ́ ìyàn; èmi yóò fi wọ́n Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́, àti ọwọ́ àwọn ̀wọn, àti ọwọ́ àwọn ń lépa ̀wọn, òun yóò fi ojú idà pa wọ́n, yóò wọn , bẹ́̀ ni yóò ìyọ́tàbí ṣàánú wọn.

8 "Síwájú i, sọ fún àwọn ènìyàn, Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ó sọ: ó, Èmi ń fi ̀ìyè àti ikú hàn yín. 9 Ẹnikẹ́ni ó dúró ìlú yìí yóò ti ipa idà, ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn . Ṣùgbọ́n ẹni ó jáde ó jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn Babeli ó ń lépa yín yóò . Òun yóò àsálà fún ̀rẹ̀. 10 Mo ti pinnu láti jẹ ìlú yìí , ni Olúwa . A ó gbé e fún ọba Babeli, yóò run ún pẹ̀iná.

11 "̀wẹ̀, fún ìdílé ọba Juda , Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. 12 Ilé Dafidi èyí ni ̀rọ̀ Olúwa sọ:

" Ṣe ìdájọ́ ó tọ́ àràárọ̀;

yọ ́ kúrò lọ́wọ́ ẹni ó ń ni í lára

ẹni a ti lólè

bẹ́̀ kọ́ ìbínú mi yóò jáde síta, yóò iná.

Nítorí ibi a ti ṣe yóò

láìsí ẹni yóò pa á.

13 Mo kẹ̀yìn , Jerusalẹmu,

ìwọ o gbé lórí àfonífojì

lórí òkúta ó tẹ́, ni Olúwa .

Ìwọ o ti , "Ta ni ó le dojúkọ ?

Ta ni yóò wọ inú ibùgbé wa?"

14 Èmi yóò jẹ ìyà gẹ́gẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀

ni Olúwa .

Èmi yóò iná ilé rẹ̀;

yóò si gbogbo ohun ó àyíká rẹ.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também