Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 39

Ìṣubú Jerusalẹmu

1 Ó ṣe, nígbà a Jerusalẹmu, ọdún kẹsànán Sedekiah, ọba Juda, nínú oṣù kẹwàá, Nebukadnessari ọba Babeli gbógun ti Jerusalẹmu pẹ̀gbogbo ogun rẹ̀, wọ́n í. 2 ọjọ́ kẹsànán, oṣù kẹrin ọdún kọkànlá Sedekiah, ni a odi ìlú náà. 3 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli , wọ́n jókòó àárín ẹnu ibodè, àní Nergali-Ṣareseri ti Samgari, Nebo-Sarsikimu olórí ìwẹ̀, Nergali-Ṣareseri, olórí amòye, pẹ̀gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli yóò . 4 Nígbà Sedekiah ọba Juda àti àwọn ọmọ-ogun wọn, wọ́n , wọ́n kúrò ìlú alẹ́, wọ́n gba ̀ọgbà ọba lọ láàrín ẹnu ibodè pẹ̀odi méjì, wọ́n dojúkọ aginjù.

5 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn ọmọ-ogun Babeli wọn, wọ́n Sedekiah láàrín aginjù Jeriko. Wọ́n un ìgbèkùn, wọ́n u tọ Nebukadnessari ọba Babeli àti Ribla ilẹ̀ Hamati, níbi wọ́n ti ṣe ìdájọ́ rẹ̀. 6 Níbẹ̀ Ribla, ni ọba Babeli ti dúńbú àwọn ọmọ Sedekiah lójú rẹ̀, ó tún pa gbogbo àwọn ọlọ́ilẹ̀ Juda. 7 Nígbà náà ni ó fọ́ ojú Sedekiah, ó é pẹ̀̀wọ̀n láti gbé e lọ ilẹ̀ Babeli.

8 Àwọn Babeli dáná sun ààfin ọba àti ilé àwọn ènìyàn, wọ́n odi Jerusalẹmu. 9 Nebusaradani olórí àwọn ọmọ-ogun lọ ìgbèkùn Babeli pẹ̀gbogbo àwọn ó ṣẹ́nínú ìlú. 10 Ṣùgbọ́n Nebusaradani olórí ogun fi àwọn aláìní sílẹ̀ Juda, àwọn ohun kankan àkókò náà, ó fún wọn ọgbà àjàrà àti oko.

11 Nísinsin yìí, Nebukadnessari ọba àwọn Babeli pàṣẹ lórí Jeremiah, láti ̀dọ̀ Nebusaradani olórí ogun : 12 "gbé e, bojútó o. ṣe ṣe ohun búburú fún un, ṣùgbọ́n ohunkóhun béèrè ni fi fún un." 13 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ pẹ̀, Nebusaradani balógun ìṣọ́, àti Nebusaradani olórí ìwẹ̀, àti Nergali-Ṣareseri, olórí amòye àti gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli, 14 ránṣẹ́ láti Jeremiah kúrò nínú túbú. Wọ́n gbé e lọ fún Gedaliah ọmọ Ahikamu ọmọ Ṣafani láti padà lọ ilé àti máa pẹ̀àwọn ènìyàn rẹ̀.

15 Nígbà Jeremiah nínú túbú, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ́ : 16 "Lọ sọ fún Ebedimeleki ará Kuṣi, Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli : Èmi ṣetán láti ̀rọ̀ mi ṣẹ lórí ìlú yìí nípa àjálù í ṣe àlàáfíà. àkókò náà ni yóò ṣẹ lójú rẹ. 17 Ṣùgbọ́n, Èmi yóò gbà ́ lọ́jọ́ náà ni Olúwa . A fi ́ ọwọ́ àwọn o bẹ̀. 18 Èmi yóò gbà ́ ; o ṣubú láti ipa idà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò àsálà fún ̀rẹ, nítorí ìwọ ìgbẹ́kẹ̀nínú mi, ni Olúwa .’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também