Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 48

Àṣọtẹ́lẹ̀ nípa Moabu

1 48.1-47: Isa 15.1–16.14; 25.10-12; El 25.8-11; Am 2.1-3; Sf 2.8-11. Nípa Moabu.

Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli :

"Ègbé ni fún Nebo nítorí a ó parun.

A dójútì Kiriataimu, a un,

ojú yóò ti alágbára, a ó fọ́nká.

2 Moabu ìyìn mọ́,

Heṣboni ni wọn ó pète ìparun rẹ̀,

, a pa orílẹ̀-èdè náà run.

Àti ̀yin òmùgọ̀ ọkùnrin pàápàá ni a ó pa lẹ́nu mọ́,

a ó fi idà e yín.

3 Gbọ́ igbe Horonaimu,

igbe ìrora àti ìparun ńlá.

4 Moabu yóò di wíwó palẹ̀;

àwọn ọmọdé rẹ̀ yóò kígbe síta.

5 Wọ́n gòkè lọ Luhiti,

wọ́n ń sọkún kíkorò wọ́n ti ń lọ;

ojú ̀Horonaimu

igbe ìrora ìparun ni à ń gbọ́ lọ.

6 ! Àsálà fún ̀yín;

dàbí aláìní aginjù.

7 Níwọ́n ìgbà o gbẹ́kẹ̀agbára àti ọrọ̀ rẹ,

a ó ìwọ náà ìgbèkùn,

Kemoṣi náà yóò lọ ilẹ̀ ìgbèkùn

pẹ̀àlùfáà àti àwọn aláṣẹ rẹ̀.

8 Gbogbo ìlú rẹ ni apanirun yóò dojúkọ,

ìlú kan le .

Àfonífojì yóò di ahoro

àti ilẹ̀ títẹ́ ni a ó run,

nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀.

9 Fi iyọ̀ Moabu,

nítorí yóò ṣègbé,

àwọn ìlú rẹ yóò di ahoro

láìsí ẹni yóò gbé inú rẹ̀.

10 "Ìfibú ni fún ẹni ó fi ìmẹ́lẹ́ ṣe iṣẹ́ Olúwa,

ìfibú ni fún ẹni ó pa idà mọ́ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀.

11 "Moabu ti ìsinmi láti ìgbà èwe rẹ̀

i ọtí wáìnì lórí gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ rẹ̀,

a láti ìgò kan èkejì

ì lọ ilẹ̀ ìgbèkùn .

Ó dùn lẹ́nu ó ti yẹ,

òórùn rẹ̀ padà.

12 Ṣùgbọ́n ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa ,

"nígbà n ó rán àwọn ó n da ọtí láti inú àwọn ìgò

wọ́n ó á síta;

wọn ó sọ àwọn ìgò rẹ̀ di òfo,

wọn ó fọ́ àwọn ife rẹ̀.

13 Nígbà náà Moabu yóò u nítorí Kemoṣi,

ojú ti í ti ilé Israẹli

nígbà ó gbẹ́kẹ̀Beteli.

14 "Báwo ni o ṣe sọ , Ajagun ni ,

alágbára ogun jíjà?

15 A ó pa Moabu run, a ó gba àwọn ìlú rẹ̀;

a ó dúńbú àwọn arẹwà ọkùnrin rẹ̀,"

ni ọba , ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

16 "Ìṣubú Moabu súnmọ́;

ìpọ́njú yóò kánkán.

17 dárò fún, gbogbo ̀yin ó i

gbogbo ̀yin mọ ó ti òkìkí .

sọ , Báwo ni ̀agbára rẹ

títóbi ó lógo ṣe fọ́!’

18 "Sọ̀kalẹ̀ níbi ògo rẹ,

o jókòó ilẹ̀ gbígbẹ,

̀yin olùgbé ọmọbìnrin Diboni,

nítorí ẹni ó pa Moabu run

yóò dojúkọ ́

yóò pa àwọn ìlú olódi rẹ run.

19 Dúró lẹ́bàá ̀o wòran,

ìwọ ń gbé Aroeri.

ọkùnrin ó sálọ àti obìnrin ó ń àsálà

ni ohun ó ṣẹlẹ̀?’

20 Ojú ti Moabu nítorí a o lulẹ̀.

hu, kígbe!

kéde rẹ̀ Arnoni ,

a pa Moabu run.

21 Ìdájọ́ ti àwọn òkè pẹrẹsẹ,

sórí Holoni, Jahisa àti Mefaati,

22 sórí Diboni, Nebo àti Beti-Diblataimu,

23 sórí Kiriataimu, Beti-Gamu àti Beti-Meoni,

24 sórí Kerioti àti Bosra,

sórí gbogbo ìlú Moabu, nítòsí àti ̀jíjìn.

25 A ìwo Moabu kúrò,

apá rẹ̀ ,"

ni Olúwa .

26 "jẹ́ a u mutí

nítorí ó ìdọ̀Olúwa,

jẹ́ Moabu lúwẹ̀́ nínú èébì rẹ̀,

ó di ẹni ̀gàn.

27 Ǹjẹ́ Israẹli di ẹni ̀gàn rẹ?

Ǹjẹ́ a o pẹ̀àwọn olè

bẹ́̀ o ń gbọn orí rẹ̀ pẹ̀yẹ̀yẹ́

nígbàkígbà a sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀?

28 Kúrò àwọn ìlú rẹ, o máa gbé láàrín àwọn òkúta,

̀yin ó ti ń gbé inú ìlú Moabu.

dàbí i àdàbà ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀

ẹnu ihò.

29 "A ti gbọ́ nípa ìgbéraga Moabu:

àti ìwà mo gbọ́n tan rẹ̀

àti ìgbéraga ọkàn rẹ̀.

30 Mo mọ àfojúdi rẹ̀, ṣùgbọ́n òfo ni," ni Olúwa ,

"ìfọ́nnu rẹ̀ ṣe nǹkan kan.

31 Nítorí náà, mo pohùnréré ẹkún lórí Moabu

fún àwọn ará Moabu ni mo kígbe lóhùn rara,

mo kẹ́dùn fún àwọn ọkùnrin Kiri-Hareseti.

32 Mo sọkún fún Jaseri ṣe sọkún

ìwọ àjàrà Sibma.

̀ka rẹ tẹ̀ títí Òkun,

wọn Òkun Jaseri.

Ajẹnirun ti kọlu èso rẹ,

ìkórè èso àjàrà rẹ.

33 Ayọ̀ àti ìdùnnú ti kúrò

nínú ọgbà àjàrà àti oko Moabu.

Mo ọwọ́ ṣíṣàn ọtí wáìnì dúró lọ́dọ̀ olùfúntí;

ẹni ó ń tẹ̀ wọ́n pẹ̀igbe ayọ̀.

ó tilẹ̀ jẹ́ igbe ,

wọn í ṣe igbe ti ayọ̀.

34 "Ohùn igbe wọn gòkè

láti Heṣboni Eleale àti Jahasi,

láti Soari títí Horonaimu àti Eglati-Ṣeliṣi,

nítorí àwọn omi Nimrimu pẹ̀yóò gbẹ.

35 ti Moabu ni èmi yóò ti fi òpin

ẹni ó ẹbọ ibí gíga

àti ẹni ń sun tùràrí fún òrìṣà rẹ̀,"

ni Olúwa .

36 "Nítorí náà ọkàn mi fún Moabu fèrè,

ọkàn mi fèrè fún àwọn ọkùnrin Kiri-Hareseti.

Nítorí ìṣúra ó kójọ ṣègbé.

37 Gbogbo orí ni yóò ,

gbogbo irùngbọ̀n ni a ó kúrò,

gbogbo ọwọ́ ni a lọ́gbẹ́,

àti aṣọ ̀fọ̀ gbogbo ̀gbẹ́.

38 Ẹkún ńlá yóò lórí gbogbo òrùlé Moabu,

àti ìta rẹ̀,

nítorí èmi ti fọ́ Moabu

a ti ń fọ́ ohun èlò wu ni,"

ni Olúwa .

39 "Èéṣe fi fọ́ túútúú,

fi ń pohùnréré ẹkún!

Báwo ni Moabu ṣe

̀yìn padà ìtìjú!

Moabu ti di ẹni ìtìjú àti ̀gàn àti

ìdààmú gbogbo àwọn ó yìí ."

40 Báyìí ni Olúwa :

"ó ẹyẹ idì náà ń bọ̀ nílẹ̀

ó na ìyẹ́ rẹ̀ lórí Moabu.

41 Kerioti ni a ó lẹ́àti ilé agbára ni ó gbà.

ọjọ́ náà ọkàn àwọn akọni Moabu

yóò dàbí ọkàn obìnrin ó ń rọbí.

42 A ó pa Moabu run gẹ́gẹ́

orílẹ̀-èdè nítorí ó gbéraga Olúwa.

43 ̀àti ̀fìn àti okùn dídè

ń dúró yín, ̀yin ènìyàn Moabu,"

Olúwa .

44 "Ẹnikẹ́ni ó fún

̀yóò ṣubú sínú ̀fìn

ẹnikẹ́ni o jáde síta

nínú ̀fìn à ó

nínú okùn dídè nítorí

èmi yóò sórí

Moabu àní ọdún ìjìyà rẹ,"

Olúwa .

45 "abẹ́ òjìji Heṣboni

àwọn ó dúró láìní agbára,

nítorí iná ti jáde láti Heṣboni,

àti ọwọ́ iná láti àárín Sihoni,

yóò iwájú orí Moabu run,

àti agbárí àwọn ọmọ aláriwo.

46 Ègbé fún Moabu!

Àwọn ènìyàn orílẹ̀-èdè Kemoṣi ṣègbé

a àwọn ọmọkùnrin rẹ lọ ilẹ̀ àjèjì

àti àwọn ọmọbìnrin rẹ lọ ìgbèkùn.

47 "Síbẹ̀, èmi yóò ìkólọ

Moabu padà ọjọ́ ìkẹyìn,"

ni Olúwa .

Eléyìí ìdájọ́ ìkẹyìn lórí Moabu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também