Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 2

Israẹli kọ Ọlọ́run sílẹ̀

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Lọ o kéde etí Jerusalẹmu :

"Báyìí ni Olúwa ,

" Èmi rántí ìṣeun ìgbà èwe rẹ,

ìfẹ́ ìgbéyàwó rẹ

àti nígbà ìwọ tẹ̀mi nínú ijù,

nínú ìyàngbẹ ilẹ̀.

3 Israẹli jẹ́ mímọ́ Olúwa,

àkọ́kọ́ èso ìkórè rẹ̀,

gbogbo ẹnikẹ́ni ó jẹ run ni a ó lẹ́bi,

ibi yóò orí wọn,’ "

bẹ́̀ ni Olúwa .

4 Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, ̀yin ìdílé Jakọbu

àti gbogbo ̀yin ará ilé Israẹli.

5 Báyìí ni Olúwa :

"Irú àìṣedéédéé wo ni baba yín lọ́wọ́ mi,

wọ́n fi jìnnà mi?

Wọ́n tẹ̀àwọn òrìṣà asán,

àwọn fúnra wọn di asán.

6 Wọn béèrè, Níbo ni Olúwa ,

ó wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti ,

ó wa la aginjù ,

ó wa la àárín pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti ihò,

ìyàngbẹ ilẹ̀ àti òkùnkùn biribiri,

ilẹ̀ ibi ẹnikẹ́ni kọjá, ẹnikẹ́ni tẹ̀?

7 Èmi yín ilẹ̀ ọlọ́ràá

láti máa jẹ èso ibẹ̀ àti ọrọ̀ rẹ̀,

ṣùgbọ́n ̀yin wọ inú rẹ̀, á jẹ́,

sọ ogún mi di ohun ìríra.

8 Àwọn àlùfáà béèrè ,

Níbo ni Olúwa ?

Àwọn ń ṣiṣẹ́ pẹ̀òfin si mọ̀ ,

àwọn olùṣọ́ ṣẹ̀ mi.

Àwọn wòlíì ń sọtẹ́lẹ̀ nípa òrìṣà Baali,

wọ́n ń tẹ̀àwọn òrìṣà asán.

9 "Nítorí náà, mo fi ̀sùn kàn yín lẹ́̀kan i,"

ni Olúwa .

"Èmi ó fi ̀sùn kan àwọn ọmọ ọwọ́ rẹ.

10 Rékọjá lọ erékùṣù àwọn ara Kittimu, ó,

ránṣẹ́ lọ ìlú Kedari, kíyèsi gidigidi;

irú nǹkan báyìí ń bẹ níbẹ̀?

11 Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ ?

(Síbẹ̀, wọ́n í ṣe iṣẹ́ ọlọ́run.)

Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi ti pààrọ̀

Ọlọ́run ògo wọn fún àwọn ère níyì.

12 Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì

wárìrì pẹ̀ìbẹ̀ńlá,"

ni Olúwa .

13 "Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì,

wọ́n ti kọ̀ sílẹ̀,

Èmi orísun omi ìyè,

wọ́n ti ṣe àmù,

àmù fífọ́ gba omi dúró.

14 Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí?

ha a ó fi di ìkógun?

15 Àwọn kìnnìún ramúramù;

wọ́n ń mọ́ wọn.

Wọ́n ti fi ilẹ̀ rẹ̀ ṣòfò;

ìlú rẹ̀ ti di jíjóná, ó ti di ìkọ̀sílẹ̀.

16 Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi

wọ́n ti fa adé orí rẹ yọ.

17 ̀yin ha a ti fa èyí sórí ara yín

nípa kíkọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀

nígbà ó tọ́ lójú ̀?

18 o ṣe lọ Ejibiti

láti lọ mu omi Ṣihori?

o fi lọ Asiria

láti lọ omi ni odò Eufurate náà?

19 Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín

ìpadàsẹ́yìn rẹ yóò

mọ̀ o i ibi àti

ohun búburú yóò jẹ́ tìrẹ

nígbà o ti kọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀,

ìbẹ̀fún mi,"

ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

20 "Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù,

ìwọ ìdè rẹ;

ìwọ , Èmi yóò sìn ́!’

Lóòtítọ́, lórí gbogbo òkè gíga ni

àti lábẹ́ igi ó tànkálẹ̀

ni ìwọ dùbúlẹ̀ gẹ́gẹ́ panṣágà.

21 Èmi ti gbìn ́ gẹ́gẹ́ àjàrà ̀tọ̀,

gẹ́gẹ́ ìṣúra ọlọ́.

Báwo ni ìwọ ṣe yípadà mi

di àjàrà búburú àti aláìmọ́?

22 ó tilẹ̀ jẹ́ o wẹ ara rẹ pẹ̀sódà

o lo ̀pọ̀lọpọ̀ ọṣẹ

síbẹ̀síbẹ̀ èérí ni ̀ṣẹ̀ rẹ níwájú,"

ni Olúwa Olódùmarè .

23 "Báwo ni ìwọ ṣe , Èmi ṣe aláìmọ́,

Èmi à tẹ̀àwọn Baali?

Wo o ṣe hùwà àfonífojì;

wo ohun o ṣe.

Ìwọ jẹ́ abo ìbákasẹ

ń síyìn-ín sọ́hùn-ún.

24 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó ń gbé aginjù

ń fa ̀fúùfù ìfẹ́ i mu rẹ,

ta ni ó le è dúró àkókò rẹ̀?

gbogbo àwọn akọ ẹran o a kiri ó ṣe ara wọn lágara,

nítorí wọn yóò àkókò oṣù rẹ̀.

25 ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà,

àti ̀fun rẹ nínú òǹgbẹ.

Ṣùgbọ́n ìwọ , Asán ni!

Èmi fẹ́ràn àwọn ọlọ́run àjèjì,

àwọn ni èmi yóò tọ̀ lẹ́yìn.

26 "Gẹ́gẹ́ a ṣe ń dójútì olè nígbà a u,

bẹ́̀ náà ni ojú yóò ti ilé Israẹli

àwọn ọba àti àwọn ìjòyè wọn,

àwọn àlùfáà àti wòlíì wọn pẹ̀.

27 Wọ́n sọ fún igi , Ìwọ ni baba mi,

àti òkúta , Ìwọ ni ó mi,

wọ́n ti kọ ̀yìn wọn mi,

wọn kọ ojú mi

síbẹ̀ nígbà wọ́n nínú ìṣòro,

wọn yóò , o gbà !

28 Níbo ni àwọn ọlọ́run ṣe fúnra yín ha a ?

Jẹ́ wọ́n wọ́n gbà yín

nígbà nínú ìṣòro!

Nítorí ̀yin àwọn ọlọ́run púpọ̀,

gẹ́gẹ́ ti ṣe ni àwọn ìlú, ìwọ Juda.

29 "o ṣe ń fi ̀sùn kàn ?

Gbogbo yín ni ó ti ṣọ̀tẹ̀ mi,"

ni Olúwa .

30 "Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín,

wọn gba ìbáwí.

Idà yín ti pa àwọn wòlíì yín run,

gẹ́gẹ́ kìnnìún ń ramúramù.

31 "̀yin ìran yìí, kíyèsi ̀rọ̀ Olúwa:

"Mo ha ti di aginjù Israẹli

tàbí mo jẹ ilẹ̀ olókùnkùn biribiri?

Èéṣe àwọn ènìyàn mi ṣe , A àǹfààní láti máa rìn kiri;

àwa yóò tọ̀ ́ mọ́?’

32 Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ̀ṣọ́ rẹ̀,

tàbí ìyàwó ohun ̀ṣọ́ ìgbéyàwó rẹ̀?

Síbẹ̀, àwọn ènìyàn mi ti gbàgbé mi

ọjọ́ àìníye.

33 Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n nípa ̀rọ̀ ìfẹ́!

Àwọn obìnrin búburú yóò kẹ́kọ̀́ nípa ̀rẹ.

34 Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n

̀jẹ̀ àwọn tálákà aláìṣẹ̀,

ó tilẹ̀ jẹ́ ìwọ wọn mọ́ níbi wọ́n ti ń rùn wọlé.

Síbẹ̀ nínú gbogbo èyí

35 ìwọ sọ , Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀;

bínú mi.

Èmi yóò ìdájọ́ mi sórí rẹ

nítorí ìwọ , Èmi dẹ́ṣẹ̀.’

36 Èéṣe ìwọ fi ń lọ káàkiri

láti ̀rẹ padà?

Ejibiti yóò dójútì ́

gẹ́gẹ́ i ti Asiria.

37 Ìwọ yóò fi ibẹ̀ sílẹ̀

pẹ̀kíkáwọ́ rẹ orí rẹ,

nítorí Olúwa ti kọ̀ àwọn ìwọ gbẹ́kẹ̀sílẹ̀,

yóò ìrànlọ́wọ́ kankan fún láti ̀dọ̀ wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também