Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 21

Ọgbà àjàrà Naboti

1 Ó ṣe lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Naboti ará Jesreeli ọgbà àjàrà kan Jesreeli, ̀gbẹ́ ààfin Ahabu ọba Samaria. 2 Ahabu fún Naboti , "Fún mi ọgbà àjàrà rẹ, èmi ó fi ṣe ọgbà-ewébẹ̀, nítorí ó súnmọ́ tòsí ilé mi, èmi yóò fún ọgbà àjàrà ó sàn ú lọ dípò rẹ̀; tàbí ó dára ojú rẹ, èmi yóò fi iye owó rẹ̀ fún ."

3 Ṣùgbọ́n Naboti fún Ahabu , "Olúwa jẹ́ èmi fi ogún àwọn baba mi fún ."

4 Ahabu ilé rẹ̀, ó wugbọ́, inú rẹ̀ bàjẹ́ nítorí ̀rọ̀ Naboti ará Jesreeli sọ fún un; nítorí ó , "Èmi yóò fún ogún àwọn baba mi." Ó dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀, ó ojú rẹ̀ padà, fẹ́ jẹun.

5 Jesebeli aya rẹ̀ tọ̀ ́ , ó béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Èéṣe inú rẹ fi bàjẹ́, èéṣe ìwọ jẹun?"

6 Ó a lóhùn , "Nítorí mo fún Naboti ará Jesreeli , Ta ọgbà àjàrà rẹ fún mi, tàbí ó ́, èmi yóò fún ọgbà àjàrà mìíràn ipò rẹ̀.’ Ṣùgbọ́n ó , Èmi yóò fún ọgbà àjàrà mi.’ "

7 Jesebeli aya rẹ̀ , "Ṣé báyìí ni ìwọ yóò ṣe ṣe ọba lórí Israẹli? Dìde, jẹun! o jẹ́ inú rẹ̀ dùn. Èmi yóò fún ọgbà àjàrà Naboti ará Jesreeli."

8 Bẹ́̀ ni ó kọ̀orúkọ Ahabu, ó fi èdìdì rẹ̀ í, ó fi ìwé náà ránṣẹ́ àwọn àgbàgbà àti àwọn ọlọ́ó ń gbé ìlú Naboti pẹ̀rẹ̀. 9 Nínú àwọn ìwé náà, ó kọ ,

"kéde àwẹ̀, fi Naboti ipò ọlá láàrín àwọn ènìyàn. 10 Ṣùgbọ́n fi ènìyàn méjì, ẹni búburú síwájú rẹ̀ láti jẹ́rìí i , ó Ọlọ́run àti ọba. Nígbà náà ni u jáde, sọ ́ òkúta pa."

11 Bẹ́̀ ni àwọn àgbàgbà àti àwọn ọlọ́wọ́n ń ṣe ará ìlú Naboti ṣe gẹ́gẹ́ ìwé Jesebeli kọ ránṣẹ́ wọn. 12 Wọ́n kéde àwẹ̀, wọ́n fi Naboti ipò ọlá láàrín àwọn ènìyàn. 13 Bẹ́̀ ni àwọn ọkùnrin méjì , àwọn ẹni búburú, wọ́n jókòó síwájú rẹ̀, wọ́n jẹ́rìí lòdì Naboti níwájú àwọn ènìyàn , "Naboti ti Ọlọ́run àti ọba." Nígbà náà ni wọ́n jáde kúrò ìlú, wọ́n sọ ́ òkúta pa. 14 Nígbà náà ni wọ́n ránṣẹ́ Jesebeli , "A ti sọ Naboti òkúta, ó ."

15 Jesebeli ti gbọ́ , a ti sọ Naboti Òkúta pa, ó fún Ahabu , "Dìde! o jogún ọgbà àjàrà Naboti, ará Jesreeli, ó kọ̀ láti fún láààyè mọ́, ó ti ." 16 Nígbà Ahabu gbọ́ Naboti ti , ó dìde, ó sọ̀kalẹ̀ lọ láti jogún ọgbà àjàrà Naboti.

17 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Elijah ará Tiṣibi , 18 "Sọ̀kalẹ̀ lọ láti lọ pàdé Ahabu ọba Israẹli, ó Samaria. Ó ọgbà àjàrà Naboti báyìí, níbi ó sọ̀kalẹ̀ lọ láti jogún rẹ̀. 19 Sọ fún un , Báyìí ni Olúwa : Ǹjẹ́ ìwọ ti pa ènìyàn, o ti fi agbára gba ogún rẹ̀?’ Nígbà náà ni o fún un , Báyìí ni Olúwa : Níbi ajá gbé ̀jẹ̀ Naboti, ni àwọn ajá yóò ̀jẹ̀ rẹ, àní tìrẹ!’ "

20 Ahabu fún Elijah , "Ìwọ ti mi, ìwọ ̀mi!"

Ó dáhùn , "Èmi ti , nítorí ìwọ ti tan ara rẹ láti ṣe búburú níwájú Olúwa. 21 Èmi yóò ibi sórí rẹ. Èmi yóò ìran rẹ kúrò, èmi yóò kúrò lọ́dọ̀ Ahabu gbogbo ọmọdé ọkùnrin, àti ọmọ ̀dọ̀, àti òmìnira Israẹli. 22 Èmi yóò ṣe ilé rẹ ilé Jeroboamu, ọmọ Nebati, àti ilé Baaṣa, ọmọ Ahijah, nítorí ìwọ ti mi bínú, ìwọ ti Israẹli ṣẹ̀.’

23 21.23: 2Ọb 9.36. "Àti ti Jesebeli pẹ̀Olúwa , Àwọn ajá yóò jẹ Jesebeli nínú yàrá Jesreeli.

24 "Àwọn ajá yóò jẹ ẹni Ahabu ó ìlú, àwọn ẹyẹ ojú ̀run yóò jẹ àwọn ẹni ó igbó."

25 (ẹnìkan Ahabu ó ta ara rẹ̀ láti ṣe búburú níwájú Olúwa, ẹni Jesebeli aya rẹ̀ ń . 26 Ó ṣe ohun ìríra gidigidi tọ òrìṣà lẹ́yìn, gẹ́gẹ́ gbogbo ohun àwọn ará Amori ti ṣe, Olúwa jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli.)

27 Nígbà Ahabu gbọ́ àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó fi aṣọ ̀fọ̀ ara rẹ̀, ó gbààwẹ̀. Ó dùbúlẹ̀ nínú aṣọ ̀fọ̀, ó ń lọ jẹ́́.

28 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Elijah ará Tiṣibi , 29 "Ǹjẹ́ ìwọ ti Ahabu ti rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú mi? Nítorí ó ti rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀, èmi yóò ibi náà ọjọ́ rẹ, ṣùgbọ́n èmi yóò u ilé rẹ̀ ọjọ́ ọmọ rẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também