Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 16

1 Ó ṣe, ̀rọ̀ Olúwa tọ Jehu ọmọ Hanani Baaṣa , 2 "Èmi ti gbé ga láti inú erùpẹ̀ , mo fi ́ ṣe olórí Israẹli ènìyàn mi, ṣùgbọ́n ìwọ rìn ̀Jeroboamu, ó Israẹli ènìyàn mi dẹ́ṣẹ̀, láti mi bínú nípa ̀ṣẹ̀ wọn. 3 Nítorí náà, èmi yóò Baaṣa àti ilé rẹ̀ kúrò, èmi yóò ṣe ilé rẹ̀ ilé Jeroboamu ọmọ Nebati. 4 Àwọn ajá yóò jẹ ẹni Baaṣa ó ìlú, ẹyẹ ojú ̀run yóò jẹ àwọn ó oko."

5 Àti ìyókù ìṣe Baaṣa, ohun ó ṣe àti agbára rẹ̀, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli? 6 Baaṣa sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín Tirsa. Ela ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

7 ̀rọ̀ Olúwa nípa ọwọ́ Jehu wòlíì ọmọ Hanani pẹ̀Baaṣa àti ilé rẹ̀, nítorí gbogbo búburú ó ti ṣe níwájú Olúwa, mímú un bínú nípa ohun ti ṣe àti wíwà ilé Jeroboamu, àti nítorí ó pa á run pẹ̀.

Ela ọba Israẹli

8 ọdún kẹrìndínlọ́gbọ̀n Asa ọba Juda, Ela ọmọ Baaṣa bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba Israẹli, ó jẹ ọba Tirsa ọdún méjì.

9 Simri, ̀kan nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, olórí ìdajì kẹ̀kẹ́ rẹ̀, dìtẹ̀ i. Ela Tirsa nígbà náà, ó mu àmupara ilé Arsa, ìríjú ilé rẹ̀ ni Tirsa. 10 Simri wọlé, ó kọlù ú, ó pa á ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n Asa, ọba Juda, ó jẹ ọba ipò rẹ̀.

11 ó ti bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba, ó ti jókòó lórí ìtẹ́, ó lu gbogbo ilé Baaṣa pa, ku ọkùnrin kan sílẹ̀, bóyá ìbátan tàbí ̀rẹ́. 12 Bẹ́̀ ni Simri pa gbogbo ilé Baaṣa run, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa ó sọ Baaṣa nípa ọwọ́ Jehu wòlíì: 13 nítorí gbogbo ̀ṣẹ̀ Baaṣa àti Ela ọmọ rẹ̀ ti ṣẹ̀ àti wọ́n ti Israẹli ṣẹ̀, wọ́n fi Olúwa Ọlọ́run Israẹli bínú, wọ́n u bínú nípa òrìṣà asán wọn.

14 Ìyókù ìṣe Ela àti gbogbo ohun ó ṣe, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?

Simri ọba Israẹli

15 ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n Asa ọba Juda, ni Simri jẹ ọba ọjọ́ méje Tirsa. Àwọn ọmọ-ogun ti Gibetoni, ìlú àwọn ará Filistini. 16 Nígbà àwọn ọmọ Israẹli ó gbọ́ Simri ti dìtẹ̀ ọba, ó ti pa á, wọ́n kéde Omri, olórí ogun, ọba lórí Israẹli ọjọ́ náà ibùdó. 17 Nígbà náà ni Omri àti gbogbo Israẹli pẹ̀rẹ̀ kúrò Gibetoni, wọ́n ti Tirsa. 18 Nígbà Simri ri a ti gba ìlú, ó wọ inú ààfin ilé ọba lọ, ó tẹ iná bọ ilé ọba lórí ara rẹ̀, ó , 19 nítorí àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ó ti ṣẹ̀, ṣíṣe búburú níwájú Olúwa àti rírìn ̀Jeroboamu àti nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ó ti ṣe àti ó ti Israẹli ṣẹ̀.

20 ti ìyókù ìṣe Simri, àti ̀tẹ̀ rẹ̀ ó , a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?

Omri ọba Israẹli

21 Nígbà náà àwọn ènìyàn Israẹli méjì; apá kan wọn ń tọ Tibni ọmọ Ginati lẹ́yìn, láti fi í jẹ ọba, apá kan tókù ń tọ Omri lẹ́yìn. 22 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ń tọ Omri lẹ́yìn borí àwọn ń tọ Tibni ọmọ Ginati lẹ́yìn. Bẹ́̀ ni Tibni , Omri jẹ ọba.

23 ọdún kọkànlélọ́gbọ̀n Asa ọba Juda, Omri bẹ̀rẹ̀ ń jẹ ọba lórí Israẹli, ó jẹ ọba ọdún méjìlá, ọdún mẹ́Tirsa. 24 Ó ra òkè Samaria lọ́wọ́ Ṣemeri tálẹ́ǹtì méjì fàdákà, ó kọ́ ìlú sórí rẹ̀, ó pe ìlú náà Samaria, nípa orúkọ Ṣemeri, orúkọ ẹni ó kọ́kọ́ ni òkè náà.

25 Ṣùgbọ́n Omri ṣe búburú níwájú Olúwa, Ó ṣe búburú ju gbogbo àwọn ó ṣáájú rẹ̀ lọ. 26 Ó rìn gbogbo ̀Jeroboamu ọmọ Nebati àti nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èyí ó ti Israẹli ṣẹ̀, láti fi ohun asán wọn Olúwa, Ọlọ́run Israẹli bínú.

27 Ìyókù ìṣe àti ohun Omri ṣe, àti agbára rẹ ó fihàn, a ha kọ, wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli? 28 Omri sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀ a sin ín Samaria. Ahabu ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Ahabu Jọba lórí Israẹli

29 ọdún kejìdínlógójì Asa ọba Juda, Ahabu ọmọ Omri jẹ ọba Israẹli, o si jẹ ọba lórí Israẹli Samaria ọdún méjìlélógún. 30 Ahabu ọmọ Omri ṣe búburú ojú Olúwa ju gbogbo àwọn ó ṣáájú rẹ̀ lọ. 31 Ó ṣe ẹni ó ṣe ohun kékeré fún un láti máa rìn nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, ó Jesebeli, ọmọbìnrin Etibaali, ọba àwọn ará Sidoni aya, ó bẹ̀rẹ̀ ń sin Baali, ó bọ ́. 32 Ó tẹ́ pẹpẹ kan fún Baali nínú ilé Baali ó kọ́ Samaria. 33 Ahabu túnṣe ère òrìṣà Aṣerah, ó ṣe púpọ̀ láti Olúwa Ọlọ́run Israẹli bínú ju èyí gbogbo ọba Israẹli ó ti ṣáájú rẹ̀ ti ṣe lọ.

34 16.34: Jo 6.26. ìgbà ayé Ahabu, Hieli ará Beteli kọ́ Jeriko. Ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ ilẹ̀ Abiramu, àkọ́rẹ, ó gbé àwọn ìlẹ̀kùn ibodè rẹ̀ kọ́ Segubu àbíkẹ́yìn rẹ̀, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa ó ti ipa Joṣua ọmọ Nuni sọ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também