Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 11

Àwọn ìyàwó Solomoni

1 Solomoni ọba fẹ́ ̀pọ̀ àjèjì obìnrin yàtọ̀ ọmọbìnrin Farao, àwọn ọmọbìnrin Moabu, àti ti Ammoni, ti Edomu, ti Sidoni àti ti àwọn ọmọ Hiti. 2 Wọ́n láti orílẹ̀-èdè Olúwa ti fún àwọn ọmọ Israẹli , "̀yin gbọdọ̀ fẹ́ wọn níyàwó tàbí ọkọ, nítorí wọn yóò ọkàn yín padà òrìṣà wọn." Síbẹ̀síbẹ̀ Solomoni fàmọ́ wọn ìfẹ́. 3 Ó ̀́dẹ́gbẹ̀rin (700) obìnrin, àwọn ọmọ ọba àti ̀́dúnrún (300) àlè, àwọn ìyàwó rẹ̀ i ọkàn padà. 4 Solomoni ti di arúgbó, àwọn ìyàwó rẹ̀ i ọkàn padà ọlọ́run mìíràn, ọkàn rẹ̀ ṣe déédé pẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, gẹ́gẹ́ ọkàn Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe. 5 Solomoni tọ Aṣtoreti òrìṣà àwọn ará Sidoni lẹ́yìn, àti Moleki òrìṣà ìríra àwọn ọmọ Ammoni. 6 Bẹ́̀ ni Solomoni ṣe búburú níwájú Olúwa; tọ Olúwa lẹ́yìn pípé, Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe.

7 Lórí òkè ń bẹ níwájú Jerusalẹmu, Solomoni kọ́ ibi gíga kan fún Kemoṣi, òrìṣà ìríra Moabu, àti fún Moleki, òrìṣà ìríra àwọn ọmọ Ammoni. 8 Bẹ́̀ ni ó ṣe bẹ́̀ fún gbogbo àwọn àjèjì obìnrin rẹ̀, ẹni ń sun tùràrí, wọ́n ń ẹbọ fún òrìṣà wọn.

9 Olúwa bínú Solomoni nítorí ọkàn rẹ̀ ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ó ti fi ara hàn án lẹ́̀méjì. 10 o tilẹ̀ jẹ́ ó ti kìlọ̀ fún Solomoni ó ṣe tọ àwọn ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn, ṣùgbọ́n Solomoni pa àṣẹ Olúwa mọ́. 11 Nítorí náà Olúwa fún Solomoni , "Nítorí ìwọ ti ṣe nǹkan yìí, ìwọ pa májẹ̀mi àti àṣẹ mi mọ́, mo ti pàṣẹ fún , dájúdájú èmi yóò fa ìjọba ya kúrò lọ́wọ́ rẹ, èmi yóò fi fún ẹlòmíràn. 12 Ṣùgbọ́n, nítorí Dafidi baba rẹ, Èmi yóò ṣe é ọjọ́ rẹ. Èmi yóò á ya kúrò lọ́wọ́ ọmọ rẹ. 13 Síbẹ̀ èmi yóò fa gbogbo ìjọba náà ya, ṣùgbọ́n èmi yóò fi ̀kan fún ọmọ rẹ nítorí Dafidi ìránṣẹ́ mi, àti nítorí Jerusalẹmu èmi ti yàn."

Àwọn ̀Solomoni

14 Nígbà náà ni Olúwa gbé ̀kan dìde Solomoni, Hadadi ará Edomu ìdílé ọba ni ó ti Edomu. 15 Ó ṣe, nígbà Dafidi Edomu, Joabu olórí ogun gòkè lọ láti sin àwọn ọmọ-ogun Israẹli ti a pa lójú ogun, ó pa gbogbo ọkùnrin Edomu. 16 Nítorí Joabu àti gbogbo Israẹli dúró níbẹ̀ fún oṣù mẹ́, títí wọ́n fi pa gbogbo ọkùnrin Edomu run. 17 Ṣùgbọ́n Hadadi sálọ Ejibiti pẹ̀àwọn ará Edomu wọ́n jẹ́ ìránṣẹ́ baba rẹ̀. Hadadi ọmọdé nígbà náà. 18 Wọ́n dìde kúrò Midiani, wọ́n lọ Parani. Nígbà náà ni wọ́n ènìyàn pẹ̀wọn láti Parani , wọ́n lọ Ejibiti, sọ́dọ̀ Farao ọba Ejibiti ẹni ó fún Hadadi ilé àti ilẹ̀, ó fún un oúnjẹ.

19 Inú Farao dùn Hadadi púpọ̀ ó fi fún un arábìnrin aya rẹ̀ aya, arábìnrin Tapenesi, ayaba. 20 Arábìnrin Tapenesi ọmọkùnrin kan fún un à ń pe orúkọ rẹ̀ Genubati, ẹni Tapenesi tọ́ dàgbà ààfin ọba. Níbẹ̀ ni Genubati ń gbé pẹ̀àwọn ọmọ Farao fúnra rẹ̀.

21 Nígbà ó Ejibiti, Hadadi gbọ́ Dafidi ti sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, àti Joabu olórí ogun ti pẹ̀. Nígbà náà ni Hadadi fún Farao , "Jẹ́ n lọ, èmi ó le padà ìlú mi."

22 Farao fún un , "ni ìwọ ṣe aláìní níbí, ìwọ fi fẹ́ padà lọ ìlú rẹ?"

Hadadi , "nǹkan, ṣùgbọ́n à jẹ́ èmi ó lọ!"

23 Ọlọ́run gbé ̀mìíràn dìde Solomoni, Resoni ọmọ Eliada, ẹni ó ti kúrò lọ́dọ̀ Hadadeseri olúwa rẹ̀, ọba Soba. 24 Ó ènìyàn jọ sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó di olórí ogun ẹgbẹ́ kan, nígbà Dafidi fi pa ogun Soba run; wọ́n lọ Damasku, wọ́n ń gbé ibẹ̀, wọ́n jẹ ọba Damasku. 25 Resoni jẹ́ ̀Israẹli gbogbo ọjọ́ Solomoni, ó ń pa kún ibi ti Hadadi ṣe. Bẹ́̀ ni Resoni jẹ ọba Siria, ó ṣòdì Israẹli.

Jeroboamu ṣọ̀tẹ̀ Solomoni

26 Bákan náà Jeroboamu ọmọ Nebati ṣọ̀tẹ̀ ọba. Ó jẹ́ ̀kan lára àwọn ìránṣẹ́ Solomoni, ará Efraimu ti Sereda, ìyá rẹ̀ jẹ́ opó, orúkọ rẹ̀ ni Serua.

27 Èyí ni ìdí ó fi ṣọ̀tẹ̀ ọba: Solomoni kọ́ Millo, ó di ̀ìlú Dafidi baba rẹ̀. 28 Jeroboamu jẹ́ ọkùnrin alágbára, nígbà Solomoni ̀dọ́mọkùnrin náà ti ṣe iṣẹ́ rẹ̀ dáradára, ó fi í ṣe olórí iṣẹ́ ìrú ilé Josẹfu.

29 Ó ṣe, àkókò náà Jeroboamu ń jáde kúrò Jerusalẹmu. Wòlíì Ahijah ti Ṣilo pàdé rẹ̀ lójú ̀, ó wọ agbádá tuntun. Àwọn méjèèjì nìkan ni ó ń bẹ oko, 30 Ahijah gbá agbádá tuntun ó wọ̀ , ó á ya ̀méjìlá. 31 Nígbà náà ni ó sọ fún Jeroboamu , "̀mẹ́wàá fún ara rẹ, nítorí báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli , ó, èmi yóò fa ìjọba náà ya kúrò ọwọ́ Solomoni, èmi yóò fi ̀mẹ́wàá fún . 32 Ṣùgbọ́n nítorí ti Dafidi ìránṣẹ́ mi àti nítorí Jerusalẹmu, ìlú mo ti yàn nínú gbogbo ̀Israẹli, òun yóò ̀kan. 33 Èmi yóò ṣe èyí nítorí wọ́n ti kọ̀ sílẹ̀, wọ́n ti sin Aṣtoreti òrìṣà àwọn ará Sidoni, Kemoṣi òrìṣà àwọn ará Moabu, àti Moleki òrìṣà àwọn ọmọ Ammoni, wọn rìn ̀mi, tàbí ṣe èyí ó dára lójú mi, tàbí pa àṣẹ àti òfin mi mọ́ Dafidi baba Solomoni ti ṣe.

34 " Ṣùgbọ́n èmi yóò gba gbogbo ìjọba náà lọ́wọ́ Solomoni; èmi ti un jẹ́ olórí gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ nítorí ti Dafidi ìránṣẹ́ mi, ẹni mo yàn, ó ti pa òfin mi àti àṣẹ mi mọ́. 35 Èmi yóò gba ìjọba náà ọwọ́ ọmọ rẹ̀, èmi yóò fi ̀mẹ́wàá fún . 36 Èmi yóò fi ̀kan fún ọmọ rẹ Dafidi ìránṣẹ́ mi máa ìmọ́lẹ̀ níwájú mi nígbà gbogbo Jerusalẹmu, ìlú mo ti yàn láti fi orúkọ mi síbẹ̀. 37 Ṣùgbọ́n ti ìwọ, Èmi yóò , ìwọ yóò jẹ ọba lórí ohun gbogbo ọkàn rẹ ń fẹ́; ìwọ yóò jẹ ọba lórí Israẹli. 38 ìwọ ṣe gbogbo èyí mo pàṣẹ fún , o rìn ̀mi, o ṣe èyí ó tọ́ lójú mi nípa pípa òfin àti àṣẹ mi mọ́, i Dafidi ìránṣẹ́ mi ti ṣe, Èmi yóò pẹ̀rẹ. Èmi yóò kọ́ ilé òtítọ́ fún èyí mo kọ́ fún Dafidi, èmi yóò fi Israẹli fún . 39 Èmi yóò rẹ irú-ọmọ Dafidi sílẹ̀ nítorí èyí, ṣùgbọ́n í ṣe títí láé.’ "

40 Solomoni ̀láti pa Jeroboamu, ṣùgbọ́n Jeroboamu sálọ Ejibiti, sọ́dọ̀ Ṣiṣaki ọba Ejibiti, ó níbẹ̀ títí Solomoni fi .

Ikú Solomoni

41 Ìyókù iṣẹ́ Solomoni àti gbogbo èyí ó ṣe, àti ọgbọ́n rẹ̀, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ìṣe Solomoni ? 42 11.42-43: 2Ki 9.30,31.Solomoni jẹ ọba Jerusalẹmu lórí gbogbo Israẹli ogójì ọdún. 43 Nígbà náà ni Solomoni sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín ìlú Dafidi baba rẹ̀. Rehoboamu ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também