Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 22

Mikaiah sọtẹ́lẹ̀ nípa Ahabu

1 22.1-35: 2Ki 18.1-34. Fún ọdún mẹ́ta ogun láàrín Aramu àti Israẹli. 2 Ṣùgbọ́n ọdún kẹta, Jehoṣafati ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ láti ọba Israẹli. 3 Ọba Israẹli ti fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "Ǹjẹ́ ̀yin mọ̀ ti wa ni Ramoti Gileadi, àwa dákẹ́ síbẹ̀, a gbà á padà lọ́wọ́ ọba Aramu?"

4 Ó béèrè lọ́wọ́ Jehoṣafati , "Ṣé ìwọ yóò mi lọ láti lọ Ramoti Gileadi ?"

Jehoṣafati ọba Israẹli lóhùn , "Èmi ìwọ, ènìyàn mi ènìyàn rẹ, ẹṣin mi ẹṣin rẹ." 5 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati tún fún ọba Israẹli , "Kọ́kọ́ béèrè lọ́wọ́ Olúwa."

6 Nígbà náà ni ọba Israẹli àwọn wòlíì jọ, irinwó (400) ọkùnrin. Ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ṣé n lọ Ramoti Gileadi lọ jagun, tàbí èmi ó jọ̀wọ́ rẹ̀?"

Wọ́n dáhùn , "Lọ, nítorí Olúwa yóò fi ọba lọ́wọ́."

7 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati béèrè , "Ǹjẹ́ wòlíì Olúwa kan níhìn-ín, àwa ìbá béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?"

8 Ọba Israẹli Jehoṣafati lóhùn , "Ọkùnrin kan ṣì , lọ́dọ̀ ẹni àwa béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ṣùgbọ́n mo kórìíra rẹ̀ nítorí í sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere kan nípa mi, ṣe ibi. Mikaiah ọmọ Imla ni."

Jehoṣafati , "ọba ṣe sọ bẹ́̀."

9 Bẹ́̀ ni ọba Israẹli pe ìránṣẹ́ kan, ó , "Lọ yára Mikaiah, ọmọ Imla ."

10 Ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda jókòó lórí ìtẹ́ wọn, wọ́n wọ aṣọ ìgúnwà wọn ìta ẹnu ibodè Samaria, gbogbo àwọn wòlíì náà ń sọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn. 11 Sedekiah ọmọ Kenaana ṣe ìwo irin fún ara rẹ̀, ó , "Báyìí ni Olúwa : Wọ̀nyí ni ìwọ yóò fi kan àwọn ará Aramu títí ìwọ yóò fi run wọ́n.’ "

12 Gbogbo àwọn wòlíì tókù ń sọtẹ́lẹ̀ ohun kan náà , "Kọlu Ramoti Gileadi, o ṣẹ́gun." Wọ́n , "Nítorí Olúwa yóò fi ọba lọ́wọ́."

13 Ìránṣẹ́ ó lọ pe Mikaiah fún un , "ó, ẹnu kan náà ni ̀rọ̀ àwọn wòlíì fi jẹ́ rere fún ọba. Jẹ́ ̀rọ̀ rẹ ti àwọn tókù mu, o sọ rere."

14 Ṣùgbọ́n Mikaiah , "Olúwa ti , ohun Olúwa sọ fún mi ni èmi yóò sọ fún un."

15 Nígbà ó , ọba béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Mikaiah, ṣé a lọ Ramoti Gileadi jagun, tàbí a jọ̀wọ́ rẹ̀?"

Ó dáhùn , "Lọ, o ṣẹ́gun, nítorí Olúwa yóò fi ọba lọ́wọ́."

16 Ọba fún un , "Ìgbà mélòó ni èmi yóò fi o ṣe sọ ohun kan fún mi ṣe òtítọ́ orúkọ Olúwa?"

17 Mikaiah dáhùn , "Mo gbogbo Israẹli túká kiri lórí àwọn òkè àgùntàn olùṣọ́, Olúwa , Àwọn wọ̀nyí olúwa. Jẹ́ olúkúlùkù padà ilé rẹ̀ àlàáfíà.’ "

18 Ọba Israẹli fún Jehoṣafati , "Ǹjẹ́ èmi sọ fún sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìre kan mi ṣe ibi?"

19 Mikaiah tún , "Nítorí náà gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. Mo Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀ pẹ̀gbogbo ogun ̀run dúró apá ̀tún àti apá òsì rẹ̀. 20 Olúwa , Ta ni yóò tan Ahabu láti kọlu Ramoti Gileadi? ó tọ ikú rẹ̀ lọ níbẹ̀?’

"Ẹnìkan báyìí, ẹlòmíràn sọ òmíràn. 21 ̀kan jáde , ó dúró níwájú Olúwa, ó , Èmi yóò tàn án.

22 "Olúwa béèrè , Báwo?

"Ó , Èmi yóò jáde lọ, èmi yóò di ̀èké ẹnu gbogbo àwọn wòlíì rẹ̀.’

"Olúwa , Ìwọ yóò tàn án, ìwọ yóò borí, jáde lọ, o ṣe bẹ́̀.’

23 "Bẹ́̀ ni Olúwa ti fi ̀èké ẹnu gbogbo àwọn wòlíì rẹ wọ̀nyí. Olúwa ti sọ ibi ."

24 Nígbà náà ni Sedekiah ọmọ Kenaana dìde, ó gbá Mikaiah lójú, ó , "̀wo ni ̀Olúwa gbà lọ kúrò lọ́dọ̀ mi láti sọ̀rọ̀?"

25 Mikaiah dáhùn , "Ìwọ yóò ṣe ìwádìí ọjọ́ ìwọ yóò pamọ́ sínú ìyẹ̀."

26 Ọba Israẹli pàṣẹ , "Mikaiah, un padà sọ́dọ̀ Amoni, olórí ìlú, àti sọ́dọ̀ Joaṣi ọmọ ọba 27 , Báyìí ni ọba : fi eléyìí sínú túbú, fi oúnjẹ ìpọ́njú àti omi ìpọ́njú bọ́ , títí èmi yóò fi padà bọ̀ àlàáfíà.’ "

28 Mikaiah , "ìwọ padà bọ̀ àlàáfíà, Olúwa ti ipa mi sọ̀rọ̀." Ó tún , "kíyèsi ̀rọ̀ mi, ̀yin ènìyàn gbogbo!"

A pa Ahabu Ramoti Gileadi

29 Bẹ́̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda gòkè lọ Ramoti Gileadi. 30 Ọba Israẹli fún Jehoṣafati , "Èmi yóò pa aṣọ , èmi yóò lọ ojú ìjà, ṣùgbọ́n ìwọ yóò wọ aṣọ ìgúnwà rẹ." Bẹ́̀ ni ọba Israẹli pa aṣọ , ó lọ ojú ìjà.

31 Ọba Aramu ti pàṣẹ fún àwọn olórí kẹ̀kẹ́ rẹ̀ méjìlélọ́gbọ̀n , "ṣe ẹnìkankan , ẹni kékeré tàbí ẹni ńlá, ṣe ọba Israẹli nìkan." 32 Nígbà àwọn olórí kẹ̀kẹ́ Jehoṣafati, wọ́n , "Dájúdájú ọba Israẹli ni èyí." Bẹ́̀ ni wọ́n yípadà láti a , ṣùgbọ́n nígbà Jehoṣafati kígbe sókè, 33 àwọn olórí kẹ̀kẹ́ i í ṣe ọba Israẹli, wọ́n padà kúrò lẹ́yìn rẹ̀.

34 Ṣùgbọ́n ẹnìkan fa ọrun rẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, ó ta ọba Israẹli láàrín ìpàdé ̀irin. Ọba Israẹli fún olùtọ́kẹ̀kẹ́ rẹ̀ , "ọwọ́ rẹ , o mi jáde kúrò nínú ogun. Èmi ti gbọgbẹ́." 35 Ogun náà le ọjọ́ náà, a ọba dúró nínú kẹ̀kẹ́ kọjú àwọn ará Aramu. ̀jẹ̀ sàn jáde láti inú ọgbẹ́ rẹ̀ àárín kẹ̀kẹ́ náà, ó àṣálẹ́. 36 A kéde la ibùdó àkókò ìwọ̀-oòrùn , "Olúkúlùkù ìlú rẹ̀ àti olúkúlùkù ilẹ̀ rẹ̀!"

37 Bẹ́̀ ni ọba , a gbé e Samaria, wọ́n sin ín Samaria. 38 Wọ́n wẹ kẹ̀kẹ́ náà adágún Samaria, àwọn ajá ̀jẹ̀ rẹ̀, àwọn àgbèrè wẹ ara wọn nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa ti sọ.

39 ti ìyókù ìṣe Ahabu, àti gbogbo èyí ó ṣe, àti ilé eyín erin ó kọ́, àti gbogbo ìlú ó tẹ̀, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli? 40 Ahabu sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀. Ahasiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Jehoṣafati ọba Juda

41 Jehoṣafati ọmọ Asa, bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba lórí Juda ọdún kẹrin Ahabu ọba Israẹli. 42 Jehoṣafati jẹ́ ẹni ọdún márùndínlógójì nígbà ó bẹ̀rẹ̀ ń jẹ ọba ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Asuba ọmọbìnrin Silihi. 43 Ó rìn nínú gbogbo ̀Asa baba rẹ̀, yípadà kúrò nínú rẹ̀; ó ṣe èyí ó tọ́ ojú Olúwa. Kìkì àwọn ibi gíga ni a kúrò, àwọn ènìyàn ń ẹbọ, wọ́n ń sun tùràrí níbẹ̀. 44 Jehoṣafati àlàáfíà pẹ̀ọba Israẹli.

45 ti ìyókù ìṣe Jehoṣafati àti ìṣe agbára rẹ̀ ó ṣe, àti ó ti jagun , a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? 46 Ó pa ìyókù àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà ọjọ́ Asa baba rẹ̀ run kúrò ilẹ̀ náà. 47 Nígbà náà ọba Edomu; adelé kan ni ọba.

48 22.48,49: 2Ki 20.35-37. Jehoṣafati kan ọkọ̀ Tarṣiṣi láti lọ Ofiri fún wúrà, ṣùgbọ́n wọn lọ, nítorí àwọn ọkọ̀ náà fọ́ Esioni-Geberi. 49 ìgbà náà Ahasiah ọmọ Ahabu fún Jehoṣafati , "Jẹ́ àwọn ìránṣẹ́ mi àwọn ìránṣẹ́ rẹ lọ nínú ọkọ̀," ṣùgbọ́n Jehoṣafati kọ̀.

50 22.50: 2Ki 21.1. Nígbà náà ni Jehoṣafati sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín pẹ̀àwọn baba rẹ̀ ìlú Dafidi, baba rẹ. Jehoramu ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Ahasiah ọba Israẹli

51 Ahasiah ọmọ Ahabu bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba lórí Israẹli Samaria ọdún kẹtàdínlógún Jehoṣafati ọba Juda, ó jẹ ọba ọdún méjì lórí Israẹli. 52 Ó ṣe búburú níwájú Olúwa, nítorí ó rìn ̀baba rẹ̀, àti ̀ìyá rẹ̀, àti ̀Jeroboamu ọmọ Nebati, ó Israẹli dẹ́ṣẹ̀. 53 Ó sin Baali, ó ń bọ Baali, ó Olúwa, Ọlọ́run Israẹli bínú, gẹ́gẹ́ i baba rẹ̀ ti ṣe.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também