Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 14

Ahijah sọtẹ́lẹ̀ fún Jeroboamu

1 àkókò náà Abijah ọmọ Jeroboamu ṣàìsàn, 2 Jeroboamu fún aya rẹ̀ , "Lọ, pa ara rẹ , wọn ó ba à mọ̀ ́n aya Jeroboamu. Nígbà náà ni o lọ Ṣilo. Ahijah wòlíì níbẹ̀; ẹni ó sọ fún mi , èmi yóò jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn yìí. 3 ìṣù àkàrà mẹ́wàá pẹ̀rẹ̀, àti àkàrà wẹ́wẹ́ àti ìgò oyin, o lọ ̀dọ̀ rẹ̀. Òun yóò sọ fún ohun yóò ṣẹlẹ̀ ọmọkùnrin náà." 4 Bẹ́̀ ni aya Jeroboamu ṣe ó ti , ó lọ ilé Ahijah Ṣilo.

Ahijah ríran; ojú rẹ̀ ti fọ́ nítorí ogbó rẹ̀. 5 Ṣùgbọ́n Olúwa ti sọ fún Ahijah , "Kíyèsi i, aya Jeroboamu ń bọ̀ béèrè nípa ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ, nítorí ó ṣàìsàn, báyìí báyìí ni ìwọ ó fún un. Nígbà ó , yóò ṣe ara rẹ̀ ẹlòmíràn."

6 Bẹ́̀ ni ó , nígbà Ahijah gbọ́ ìró ẹsẹ̀ rẹ̀ ẹnu-ọ̀, ó , "Wọlé , aya Jeroboamu. ìwọ fi ṣe ara rẹ ẹlòmíràn? A ti fi iṣẹ́ búburú rán mi . 7 Lọ, sọ fún Jeroboamu báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli , Èmi gbé ga láti inú àwọn ènìyàn, mo fi ́ jẹ olórí lórí Israẹli ènìyàn mi. 8 Mo fa ìjọba náà ya kúrò ilé Dafidi, mo fi fún ṣùgbọ́n, ìwọ dàbí Dafidi ìránṣẹ́ mi, ó pa àṣẹ mi mọ́, ó tọ̀ lẹ́yìn tọkàntọkàn rẹ̀, láti ṣe kìkì èyí ó tọ́ ojú mi. 9 Ìwọ ti ṣe búburú ju gbogbo àwọn ó ti ṣáájú rẹ lọ. Ìwọ ti ṣe àwọn ọlọ́run mìíràn fún ara rẹ, àwọn òrìṣà a gbẹ́; o ti mi bínú, o ti gbé mi sọ ̀yìn rẹ.

10 " Nítorí èyí, Èmi yóò ibi ilé Jeroboamu. Èmi yóò gbogbo ̀dọ́mọkùnrin kúrò lọ́dọ̀ Jeroboamu, àti ọmọ ̀dọ̀ àti òmìnira Israẹli. Èmi yóò ilé Jeroboamu kúrò ènìyàn ti ń ìgbẹ́ kúrò, títí gbogbo rẹ̀ yóò fi tán. 11 Ajá yóò jẹ ẹni Jeroboamu ó ìlú, àti ẹni ó igbó ni àwọn ẹyẹ ojú ̀run yóò jẹ. Olúwa ti sọ ́!’

12 "ti ìwọ, padà lọ ilé, nígbà o fi ẹsẹ̀ rẹ tẹ ìlú, ọmọ náà yóò . 13 Gbogbo Israẹli yóò ṣọ̀fọ̀ fún un, wọn yóò sin ín. Òun nìkan ni a ó sin nínú ẹni ń ṣe ti Jeroboamu, nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ nìkan ni a ti ohun rere díẹ̀ sípa Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ilé Jeroboamu.

14 "Olúwa yóò gbé ọba kan dìde fúnra rẹ̀ lórí Israẹli yóò ilé Jeroboamu kúrò. Ọjọ́ náà nìyìí! ni? Àní nísinsin yìí. 15 Olúwa yóò kọlu Israẹli, yóò dàbí koríko ti ń nínú omi. Yóò fa Israẹli tu kúrò ilẹ̀ rere yìí, ó ti fi fún àwọn baba wọn, yóò fọ́n wọn kọjá odò Eufurate, nítorí wọ́n ti ìbínú Olúwa nípa ṣíṣe ère Aṣerah. 16 Yóò kọ Israẹli sílẹ̀ nítorí ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ti ṣẹ̀ àti ó Israẹli ṣẹ̀."

17 Nígbà náà ni aya Jeroboamu dìde, ó lọ, ó lọ Tirsa. ó ti fi ẹsẹ̀ tẹ ìloro ilé, ọmọdé náà . 18 Wọ́n sin ín, gbogbo Israẹli ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti láti ẹnu ìránṣẹ́ rẹ̀, Ahijah wòlíì.

19 Ìyókù ìṣe Jeroboamu, ó ti jagun, àti ó ti jẹ ọba, ni a kọ sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli. 20 Jeroboamu jẹ ọba fún ọdún méjìlélógún, ó sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀. Nadabu ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Rehoboamu ọba Juda

21 Rehoboamu ọmọ Solomoni jẹ ọba Juda. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún nígbà ó bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba, ó jẹ ọba ọdún mọ́kànlélógún Jerusalẹmu, ìlú Olúwa ti yàn nínú gbogbo ̀Israẹli láti fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Ammoni.

22 Juda ṣe búburú níwájú Olúwa nípa ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n ti , wọ́n u jowú ju gbogbo èyí baba wọn ti ṣe lọ. 23 Wọ́n tún kọ́ ibi gíga fún ara wọn, àti ère òkúta àti òpó Aṣerah lórí gbogbo òkè gíga, àti lábẹ́ gbogbo igi tútù. 24 Àwọn wọn jẹ́ ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà ilẹ̀ náà, àwọn ènìyàn náà ṣe gẹ́gẹ́ gbogbo ohun ìríra àwọn orílẹ̀-èdè Olúwa ti jáde kúrò níwájú àwọn ọmọ Israẹli.

25 14.25-31: 2Ki 12.1-16. Ó ṣe ọdún karùn-ún Rehoboamu, Ṣiṣaki ọba Ejibiti kọlu Jerusalẹmu. 26 Ó ìṣúra ilé Olúwa lọ àti ìṣúra ilé ọba. Gbogbo rẹ̀ ni ó lọ, pẹ̀asà wúrà Solomoni ti ṣe. 27 Rehoboamu ọba ṣe asà idẹ ipò wọn, ó fi wọ́n ọwọ́ olórí àwọn olùṣọ́ ń ṣọ́ ìlẹ̀kùn ilé ọba. 28 Nígbàkígbà ọba lọ ilé Olúwa, wọ́n á wọ́n, wọ́n á wọn padà sínú yàrá olùṣọ́.

29 ti ìyókù ìṣe Rehoboamu, àti gbogbo ohun ó ṣe, ǹjẹ́ a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda ? 30 Ogun láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu ọjọ́ wọn gbogbo. 31 Rehoboamu sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín pẹ̀wọn ìlú Dafidi. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama; ará Ammoni. Abijah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também