Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 7

Ṣiggaioni ti Dafidi, èyí ó kọ Olúwa nípa Kuṣi, ará Benjamini.

1 Olúwa Ọlọ́run mi, ààbò mi nínú rẹ;

gba o mi sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ń mi,

2 wọn ó ba à fa ọkàn mi ya gẹ́gẹ́ kìnnìún,

wọ́n á ya á pẹ́rẹpẹ̀rẹ láìsí ẹni yóò gbà .

3 Olúwa Ọlọ́run mi, èmi ṣe èyí

̀bi ọwọ́ mi.

4 èmi ṣe ibi ẹni ń àlàáfíà pẹ̀mi,

mo ja ̀mi lólè láìnídìí,

5 nígbà náà, jẹ́ ̀mi mi wọn mi;

jẹ́ òun ó tẹ ọkàn mi mọ́lẹ̀

wọn mi sùn nínú eruku. Sela.

6 Dìde, Olúwa, nínú ìbínú rẹ;

dìde lòdì ìrunú àwọn ̀mi.

, Ọlọ́run mi; kéde òdodo.

7 ìpéjọ àwọn ènìyàn yíká.

Jọba lórí wọn láti òkè .

8 Jẹ́ Olúwa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn.

Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa, gẹ́gẹ́ òdodo mi,

gẹ́gẹ́ ìwà òtítọ́, ẹni gíga jùlọ.

9 7.9: If 2.23. Ọlọ́run Olódodo,

Ẹni ó ń wo inú àti ọkàn,

ó ń òpin ìwà ipá ẹni búburú

ó ń pa àwọn olódodo mọ́.

10 Ààbò mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run,

ẹni ń ṣe ìgbàlà òtítọ́ àyà.

11 Ọlọ́run ni onídàájọ́ òtítọ́,

Ọlọ́run ń sọ ìrunú rẹ̀ gbogbo ọjọ́.

12 yípadà,

Òun yóò pọ́n idà rẹ̀ ;

ó ti fa ọrun rẹ̀ le , ó ti múra rẹ̀ sílẹ̀.

13 Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀;

ó ti pèsè ọfà iná sílẹ̀.

14 Ẹni ó lóyún ohun búburú,

ó lóyún wàhálà, ó èké jáde.

15 Ẹni ó gbẹ́ ̀fìn, ó o jáde

kòtò ó gbẹ́ sílẹ̀.

16 Wàhálà ó padà sórí rẹ̀;

ìwà ipá rẹ̀ padà sórí ara rẹ̀.

17 Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,

èmi ó kọrin ìyìn Olúwa ̀gá-ògo jùlọ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também