Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 44

Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Maskili.

1 À ti fi etí wa gbọ́, Ọlọ́run;

àwọn baba wa sọ fún wa

ohun ìwọ ṣe ọjọ́ wọn,

ọjọ́ pípẹ́ sẹ́yìn.

2 Ìwọ fi ọwọ́ rẹ orílẹ̀-èdè jáde,

Ìwọ gbin àwọn baba wa;

ìwọ run àwọn ènìyàn náà

Ìwọ àwọn baba wa gbilẹ̀.

3 í ṣe nípa idà wọn ni wọ́n gba ilẹ̀ náà,

bẹ́̀ ni í ṣe apá wọn ó gbà wọ́n ṣe;

ọwọ́ ̀tún rẹ̀ àti, apá rẹ;

àti ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ̀, nítorí ìwọ fẹ́ wọn.

4 Ìwọ ni ọba àti Ọlọ́run mi,

ẹni ó pàṣẹ ìṣẹ́gun fún Jakọbu.

5 Nípasẹ̀ rẹ ni àwa ó bi àwọn ̀wa ṣubú;

nípasẹ̀ orúkọ rẹ ni àwa ó tẹ àwọn ̀ó dìde wa mọ́lẹ̀,

6 èmi yóò gbẹ́kẹ̀ọrun mi,

idà mi yóò ìṣẹ́gun lórí àwọn ̀,

7 ṣùgbọ́n ìwọ fún wa ìṣẹ́gun lórí àwọn ̀wa,

ìwọ ti dójúti àwọn ó kórìíra wa.

8 Nínú Ọlọ́run àwa ń ṣògo gbogbo ọjọ́,

àwa ó yin orúkọ rẹ títí láé. Sela.

9 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ ti kọ̀ , ìwọ ti dójútì ,

Ìwọ àwọn ọmọ-ogun wa jáde mọ́.

10 Ìwọ ti wa ,

ìwọ ti ṣẹ́gun wa níwájú àwọn ̀wa,

àwọn ̀wa ti gba ilẹ̀ wa,

wọ́n fi ipá gba oko wa.

11 Ìwọ fi fún jíjẹ ẹran àgùntàn,

Ìwọ ti wa àárín àwọn kèfèrí.

12 Ìwọ ta àwọn ènìyàn rẹ fún owó kékeré,

Ìwọ jẹ èrè kankan lórí iye ìwọ wọ́n.

13 Ìwọ sọ di ẹni ̀sín ̀dọ̀ àwọn aládùúgbò wa,

ẹlẹ́àti ẹni àbùkù àwọn ó wa .

14 Ìwọ ti sọ di ẹni ìfisọ̀rọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè;

àwọn ènìyàn ń mi orí wọn wa.

15 Ìdójútì mi ń bẹ pẹ̀mi gbogbo ọjọ́,

ìtìjú bojú mi mọ́lẹ̀,

16 nítorí ̀rọ̀ ̀gàn àti ̀rọ̀ ̀tàn

ojú àwọn ̀àti olùgbẹ̀san.

17 Gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí ń ṣẹlẹ̀ wa,

síbẹ̀ àwa gbàgbé rẹ

bẹ́̀ ni a ṣèké májẹ̀rẹ̀.

18 Ọkàn wa padà sẹ́yìn;

bẹ́̀ ni ẹsẹ̀ wa yẹ̀ kúrò ̀rẹ̀.

19 Ṣùgbọ́n wọ́n kọlù ,

ìwọ sọ di ẹran ọdẹ fún àwọn ẹranko búburú,

wọn fi òkùnkùn biribiri mọ́lẹ̀.

20 àwa ti gbàgbé orúkọ Ọlọ́run wa

tàbí a na ọwọ́ wa ọlọ́run àjèjì.

21 Ǹjẹ́ Ọlọ́run yóò ìdí rẹ̀,

níwọ̀n ìgbà ó mọ ohun ìkọ̀kọ̀ inú ọkàn?

22 44.22: Ro 8.36. Síbẹ̀, nítorí rẹ̀ àwa da àyà kọ ikú, ojoojúmọ́

a ń àgùntàn fún pípa.

23 , Olúwa! Èéṣe ìwọ ń sùn?

Dìde fúnra rẹ̀! ṣe kọ̀ sílẹ̀ láéláé.

24 Èéṣe ìwọ ń pa ojú rẹ mọ́

ìwọ gbàgbé ìpọ́njú àti ìnira wa?

25 Nítorí a tẹrí ọkàn wa ba sínú eruku;

ara wa mọ́ erùpẹ̀ ilẹ̀.

26 Dìde o ràn lọ́wọ́;

padà nítorí ìfẹ́ rẹ ó dúró ṣinṣin.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também