Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 115

1 í ṣe fún wa, Olúwa í ṣe fún wa,

ṣùgbọ́n fún orúkọ rẹ ni a fi ògo fún,

fún àánú àti òtítọ́ rẹ.

2 Torí ni àwọn kèfèrí yóò ṣe sọ ,

níbo ni Ọlọ́run wa .

3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wa lọ́run:

ó ń ṣe èyí ó ú.

4 115.4-8: Sm 135.15-18. Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà,

iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.

5 Wọ́n ẹnu, ṣùgbọ́n wọn le sọ̀rọ̀,

wọ́n ojú, ṣùgbọ́n wọn fi ríran.

6 Wọ́n etí, ṣùgbọ́n wọn fi gbọ́rọ̀:

wọ́n imú, ṣùgbọ́n wọn fi gbóòórùn.

7 Wọ́n ọwọ́, ṣùgbọ́n wọn ó,

wọ́n ẹsẹ̀, ṣùgbọ́n wọn rìn;

bẹ́̀ ni wọn sọ̀rọ̀ nínú òfin wọn.

8 Àwọn ń ṣe wọ́n dàbí wọn;

gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni olúkúlùkù ẹni ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ wọn.

9 Ìwọ Israẹli gbẹ́kẹ̀Olúwa:

òun ni ìrànwọ́ àti ààbò wọn

10 ̀ yin ilé Aaroni, gbẹ́kẹ̀Olúwa:

òun ni ìrànwọ́ àti ààbò wọn.

11 ̀ yin ó bẹ̀Olúwa, gbẹ́kẹ̀Olúwa:

òun ìrànwọ́ àti ààbò wọn.

12 Olúwa ń ṣe ìrántí wa; yóò bùkún ilé Israẹli;

yóò bùkún ilé Aaroni.

13 115.13: If 11.18; 19.5. Ìbùkún ni fún àwọn ó bẹ̀Olúwa,

àti kékeré àti ńlá.

14 Olúwa yóò pọ̀ i síwájú àti síwájú,

ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀.

15 fi ìbùkún fún Olúwa

ẹni ó ̀run òun ayé.

16 ̀run àní ̀run ni ti Olúwa:

ṣùgbọ́n ayé fi fún ọmọ ènìyàn.

17 Òkú yìn Olúwa,

tàbí ẹni ó ti lọ ìsàlẹ̀ ìdákẹ́ jẹ́́.

18 Ṣùgbọ́n àwa ó fi ìbùkún fún Olúwa

láti ìsinsin yìí lọ àti títí láéláé.

yin Olúwa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também