Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 76

Fún adarí orin. Pẹ̀ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Asafu. Orin.

1 Juda ni a mọ Ọlọ́run;

orúkọ rẹ̀ lágbára Israẹli

2 Àgọ́ rẹ̀ Salẹmu,

ibùgbé rẹ̀ ni Sioni.

3 Níbẹ̀ ni ó ṣẹ́ ọfà,

asà àti àwọn idà, ohun ìjà ogun. Sela.

4 Ìwọ ni ògo àti ọlá,

ju òkè ńlá ìkógun wọ̀nyí lọ.

5 A àwọn alágídí ọkàn ìkógun

wọ́n sun oorun ìgbẹ̀yìn wọn;

̀kan nínú àwọn akọni

gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè.

6 ìfibú rẹ, Ọlọ́run Jakọbu,

àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun dùbúlẹ̀ síbẹ̀.

7 Ìwọ nìkan ni ó yẹ a bẹ̀.

Ta dúró níwájú rẹ, nígbà ìwọ ń bínú?

8 Ìwọ ń ṣe ìdájọ́ láti ̀run,

ilé ayé bẹ̀, ó dúró jẹ́́,

9 nígbà , ìwọ Ọlọ́run,

dìde láti ṣe ìdájọ́,

láti gba àwọn ẹni ìnilára ilẹ̀ náà. Sela.

10 Lóòótọ́, ìbínú rẹ àwọn ènìyàn ń ìyìn fún ,

ẹni ó yọ nínú ìbínú rẹ a nígbà ìwọ fi ìbínú ìyókù di ara rẹ ni àmùrè.

11 Jẹ́ ̀jẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ o un ṣẹ;

gbogbo àwọn ó i

̀bùn fún ẹni ó tọ́ láti bẹ̀.

12 Ó ̀àwọn aládé kúrò;

àwọn ọba ayé ń bẹ̀rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também