Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 83

Orin. Saamu ti Asafu.

1 Ọlọ́run, ṣe dákẹ́;

ṣe dákẹ́, Ọlọ́run ṣe dúró jẹ́́.

2 Wo àwọn ̀rẹ ti ń rọ́kẹ̀kẹ̀ lọ,

bi àwọn ̀rẹ ti ń gbé ohùn wọn sókè.

3 Pẹ̀àrékérekè ni wọn dìtẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ;

wọn dìtẹ̀ mọ́ àwọn o fẹ́.

4 Wọn , ", jẹ́ á pa wọ́n run orílẹ̀-èdè,

orúkọ Israẹli ma a ìrántí mọ́."

5 Wọ́n gbìmọ̀ pọ̀ pẹ̀ọkàn kan;

wọ́n ṣe àdéhùn láti ṣọ̀tẹ̀

6 Àgọ́ Edomu àti ti àwọn ará Iṣmaeli,

ti Moabu àti ti Hagari

7 Gebali, Ammoni àti Amaleki,

Filistia, pẹ̀àwọn ènìyàn Tire.

8 Asiria pẹ̀ti darapọ̀ mọ́ wọn

láti ran àwọn ọmọ Lọti lọ́wọ́. Sela.

9 Ṣe wọn ìwọ ti ṣe Midiani

o ti ṣe Sisera àti Jabini odò Kiṣoni,

10 ẹni ó ṣègbé Endori

wọn dàbí ààtàn orí ilẹ̀.

11 Ṣe àwọn ọlọ́wọn Orebu àti Seebu,

àwọn ọmọ-aládé wọn Seba àti Salmunna,

12 ó , "jẹ́ a gbà ìní

àní pápá oko tútù Ọlọ́run."

13 Ìwọ Ọlọ́run, ṣe wọ́n ààjà,

ìyàngbò níwájú afẹ́fẹ́.

14 iná ti í igbó,

àti ̀wọ́-iná ti ń òkè ńlá gbiná,

15 bẹ́̀ ni o fi ̀fúùfù líle rẹ lépa wọn

dẹ́rùbà wọn lójú pẹ̀ìjì rẹ.

16 Fi ìtìjú kún ojú wọn,

àwọn ènìyàn à ṣe àfẹ́orúkọ rẹ àti o fi ìjì líle rẹ dẹ́rùbà, ìwọ Olúwa.

17 Jẹ́ ojú ó wọ́n, wọ́n dààmú láéláé

wọ́n ṣègbé sínú ̀gàn

18 jẹ́ wọn mọ̀ ìwọ, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa:

ìwọ nìkan ̀gá-ògo jùlọ lórí gbogbo ayé.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também