Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 124

Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi.

1 "Ìbá ṣe Olúwa ó ti fún wa,"

ni Israẹli ó máa nísinsin yìí;

2 ìbá ṣe Olúwa tiwa,

nígbà àwọn ènìyàn gbógun wa,

3 nígbà náà ni wọn ò gbé láààyè

nígbà ìbínú wọn ru wa,

4 nígbà náà ni omi

wọ̀n-ọn-nì ìbá mọ́lẹ̀,

5 nígbà náà ni agbéraga

omi ìbá borí ọkàn wa.

6 Olùbùkún ni Olúwa, fi fún wọ́n

ohun ọdẹ fún eyín wọn.

7 Ọkàn wa yọ ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ;

okùn àwa yọ.

8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ orúkọ Olúwa,

ó ̀run òun ayé.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também