Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 43

1 mi láre, Ọlọ́run mi,

o gba ̀rọ̀ mi lọ́dọ̀ àwọn aláìláàánú orílẹ̀-èdè:

yọ kúrò lọ́wọ́ ẹlẹ́tàn àti àwọn ènìyàn búburú.

2 Ìwọ ni Ọlọ́run ibi agbára mi.

Èéṣe ìwọ fi kọ̀ mi sílẹ̀?

Èéṣe èmi yóò máa rìn nínú ìbìnújẹ́,

nítorí ìnilára lọ́dọ̀ àwọn ̀?

3 Rán ìmọ́lẹ̀ àti òtítọ́ rẹ jáde,

jẹ́ wọn ó máa dáàbò ;

jẹ́ wọn mi òkè mímọ́ rẹ,

ibi ìwọ ń gbé.

4 Nígbà náà ni èmi ó lọ ibi pẹpẹ Ọlọ́run,

Ọlọ́run ayọ̀ mi àti ìdùnnú mi,

èmi yóò yìn ́ pẹ̀dùùrù,

ìwọ Ọlọ́run, Ọlọ́run mi.

5 Èéṣe o fi ń rẹ̀wẹ̀, ìwọ ọkàn ?

Èéṣe ó fi ń ru sókè nínú mi?

Fi ìrètí rẹ sínú Ọlọ́run,

nítorí èmi yóò máa yìn ín, Òun ni

Olùgbàlà mi àti Ọlọ́run mi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também