Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 129

Orin fún ìgòkè.

1 "Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú

láti ìgbà èwe mi ,"

jẹ́ Israẹli ó nísinsin yìí;

2 "Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú

láti ìgbà èwe mi ;

síbẹ̀ wọn ì borí mi.

3 Àwọn awalẹ̀ walẹ̀ ̀yìn mi:

wọ́n la aporo wọn gígùn.

4 Olódodo ni Olúwa:

ó ti okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò."

5 gbogbo àwọn ó kórìíra Sioni ó dààmú,

wọn ó ̀yìn padà.

6 wọn ó dàbí koríko orí ilẹ̀

ó gbẹ dànù ó dàgbàsókè,

7 èyí olóko pípa kún ọwọ́ rẹ̀:

bẹ́̀ ni ẹni ń di ìtí, kún apá rẹ̀.

8 Bẹ́̀ ni àwọn ń kọjá lọ ,

ìbùkún Olúwa ó pẹ̀yín:

àwa ń súre fún yin orúkọ Olúwa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também