Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 140

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa, gbà mi lọ́wọ́ ọkùnrin búburú u ,

yọ lọ́wọ́ ọkùnrin ìkà a ,

2 ẹni ń ro ìwà búburú inú wọn;

nígbà gbogbo ni wọ́n ń ìjà sókè mi.

3 Wọ́n ti pọ́n ahọ́n wọn ejò,

oró paramọ́lẹ̀ ń bẹ abẹ́ ètè wọn.

4 Olúwa, pa mọ́ kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú;

yọ kúrò lọ́wọ́ ọkùnrin ìkà a

ẹni ó ti pinnu rẹ̀ láti bi ìrìn mi ṣubú.

5 Àwọn agbéraga ti dẹkùn sílẹ̀ fún mi àti okùn:

wọ́n ti na àwọ̀n lẹ́bàá ̀;

wọ́n ti kẹ́kùn sílẹ̀ fún mi.

6 Èmi fún Olúwa ìwọ ni Ọlọ́run mi;

Olúwa, gbọ́ ohùn ̀bẹ̀ mi.

7 Olúwa Olódùmarè, agbára ìgbàlà mi,

ìwọ ni ó bo orí mi mọ́lẹ̀ ọjọ́ ìjà.

8 Olúwa, máa ṣe fi ìfẹ́ ènìyàn búburú fún un;

ṣe kún ọgbọ́n búburú rẹ̀ lọ́wọ́;

wọn ó máa ba à gbé ara wọn ga. Sela.

9 ó ṣe ti orí àwọn ó mi káàkiri ni,

jẹ́ ète ìka ara wọn ó wọ́n mọ́lẹ̀.

10 A ó da ̀yin iná wọn lára,

Òun yóò wọ́ wọn lọ sínú iná,

sínú ̀gbun omi jíjìn,

wọn ó ba à le dìde mọ́.

11 ṣe jẹ́ aláhọ́n búburú fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ ayé;

ibi ni yóò máa dọdẹ ọkùnrin ìkà láti í ṣubú.

12 Èmi mọ̀ , Olúwa yóò ̀olùpọ́njú dúró,

yóò ṣe ̀tọ́ fún àwọn tálákà.

13 Nítòótọ́ àwọn olódodo yóò

máa fi ọpẹ́ fún orúkọ rẹ;

àwọn ẹni dídúró ṣinṣin yóò máa gbé iwájú rẹ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também