Pular para o conteúdo
Publicidade

Amosi 7

Eṣú, iná àti ìwọ̀n okùn

1 Èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè fihàn : Ó pèsè ọwọ́ eṣú lẹ́yìn ìgbà a kórè ìpín ọba, ìgbà ti èso ̀̀kejì ń jáde bọ̀. 2 Nígbà wọ́n jẹ koríko ilẹ̀ náà mọ́ féfé nígbà náà ni mo gbé ohùn mi sókè , "Olúwa Olódùmarè, mo bẹ̀ ́, dáríjì! Báwo ni Jakọbu yóò ha ṣe dìde? Òun kéré jọjọ!"

3 Olúwa ronúpìwàdà nípa èyí.

"Èyí ni ṣẹlẹ̀," ni Olúwa .

4 Èyí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè fihàn : Olúwa Olódùmarè ń fún ìdájọ́ pẹ̀iná; ó ̀gbun ńlá rún, ó jẹ ilẹ̀ run. 5 Nígbà náà ni mo gbé ohùn mi sókè , "Olúwa Olódùmarè jọ̀wọ́ ṣe ṣe é! Báwo ni Jakọbu yóò ha ṣe dìde? Òun kéré jọjọ!"

6 Olúwa ronúpìwàdà nípa èyí.

"Èyí náà ṣẹlẹ̀," ni Olúwa Olódùmarè .

7 Èyí ni ohun ó fihàn : Olúwa dúró ̀gbẹ́ odi ti a fi okùn ìwọ̀n mọ́, ti òun ti okùn ìwọ̀n ó rún ni ọwọ́ rẹ̀. 8 Olúwa bi mi , "Amosi, ni ìwọ ?"

Mo dáhùn , "Okùn ìwọ̀n."

Nígbà náà ni Olúwa , "ó, Èmí ń gbé okùn ìwọ̀n kalẹ̀ láàrín àwọn Israẹli ènìyàn mi; Èmi yóò tún kọjá lọ́dọ̀ wọn mọ́.

9 "Ibi gíga Isaaki wọ̀n-ọn-nì yóò di ahoro

àti ibi mímọ Israẹli wọ̀n-ọn-nì yóò di ahoro.

Èmi yóò fi idà dìde ilé Jeroboamu."

Amosi àti Amasiah

10 Nígbà náà Amasiah àlùfáà Beteli ránṣẹ́ Jeroboamu ọba Israẹli, : "Amosi ti dìde láti dìtẹ̀ ni àárín gbùngbùn Israẹli. Ilẹ̀ le gba gbogbo ̀rọ̀ rẹ̀. 11 Nítorí èyí ni ohun ti Amosi ń sọ:

" Jeroboamu yóò ti ipa idà ,

lóòtítọ́ Israẹli yóò lọ ìgbèkùn,

jìnnà kúrò ilẹ̀ ìní wọn.’ "

12 Nígbà náà ni Amasiah sọ fún Amosi , "Lọ jáde, ìwọ aríran! Padà ilẹ̀ àwọn Juda. o máa jẹun rẹ níbẹ̀, o máa sọtẹ́lẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀. 13 ṣe sọtẹ́lẹ̀ mọ ni Beteli nítorí ibi mímọ́ ọba ni àti ibi tẹmpili ìjọba rẹ̀."

14 Amosi Amasiah lóhùn , "Èmi í ṣe wòlíì tàbí àwọn ọmọ wòlíì, ṣùgbọ́n mo jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn, mo ń ṣe ìtọ́igi ̀pọ̀tọ́ sikamore. 15 Ṣùgbọ́n Olúwa mu mi mo ti ń tọ́ agbo ẹran lẹ́yìn, ó fun mi , Lọ sọtẹ́lẹ̀ fun àwọn Israẹli ènìyàn mi.16 Nítorí náà nísinsin yìí, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa. Ìwọ ,

" ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ Israẹli,

ṣe wàásù ilé Isaaki.

17 "Nítorí náà, èyí ni ohun ti Olúwa :

" Ìyàwó rẹ yóò di panṣágà ni ìlú,

àwọn ọmọ ọkùnrin àti obìnrin rẹ yóò ti ipa idà ṣubú.

A ó fi okùn wọn ilẹ̀ rẹ, a ó pín in

àti ìwọ pẹ̀yóò ni ilẹ̀ àìmọ́.

Israẹli yóò lọ ìgbèkùn,

kúrò ilẹ̀ ìní wọn.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também