Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 10

1 Ègbé ni fún àwọn ti ń ṣe òfin àìṣòdodo,

2 láti dún àwọn aláìní ̀tọ́ wọn

àti láti fa ọwọ́ ìdájọ́ sẹ́yìn kúrò níwájú àwọn olùpọ́njú ènìyàn mi,

wọ́n sọ àwọn ̀pọ̀ di ìjẹ fún wọn,

wọ́n ń ja àwọn aláìní baba lólè.

3 ni ìwọ yóò ṣe ọjọ́ ìṣirò

nígbà ìparun ti ̀jíjìn ?

Ta ni ìwọ yóò tọ̀ fún ìrànlọ́wọ́?

Níbo ni ìwọ yóò fi ọrọ̀ rẹ ?

4 Ohunkóhun ṣẹ́mọ́ ṣe láti tẹ̀ ba láàrín àwọn ìgbèkùn

tàbí o ṣubú sáàrín àwọn a pa.

Pẹ̀gbogbo nǹkan wọ̀nyí, ìbínú rẹ̀ kúrò,

ọwọ́ rẹ̀ tún gbé sókè.

Ìdájọ́ Ọlọ́run Lórí Asiria

5 10.5-34: Nh; Sf 2.13-15. "Ègbé ni fún àwọn ará Asiria, ̀gọ ìbínú mi,

ọwọ́ ẹni kùmọ̀ ìbínú mi !

6 Mo rán an orílẹ̀-èdè aláìní Ọlọ́run,

mo dojú rẹ̀ kọ àwọn ènìyàn ó mi bínú

láti ẹrù gbà, àti láti ìkógun

láti tẹ̀ mọ́lẹ̀ amọ̀ ojú òpópó.

7 Ṣùgbọ́n, èyí í ṣe ohun ó fẹ́ ṣe,

èyí kọ́ ni ohun ó lọ́kàn;

èrò rẹ̀ ni láti parun,

láti fi òpin ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè.

8 í ha ṣe ọba ni gbogbo àwọn aláṣẹ mi?ni Olúwa .

9 í ha ṣe Kalno dàbí i Karkemiṣi?

Hamati ha dàbí i Arpadi,

àti Samaria i Damasku?

10 Gẹ́gẹ́ ọwọ́ mi ti gbá ìjọba àwọn òrìṣà ,

ìjọba ère rẹ̀ pọ̀ ju ti Jerusalẹmu àti Samaria lọ.

11 Èmi yóò a Jerusalẹmu àti àwọn ère rẹ̀?’ "

Gẹ́gẹ́ mo ṣe ṣe Samaria àti àwọn ère rẹ̀?

12 Nígbà Olúwa ti ṣe iṣẹ́ rẹ̀ òkè Sioni àti Jerusalẹmu, yóò sọ , "Èmi yóò fi ìyà jẹ ọba Asiria nítorí gààrù àyà rẹ̀ àti ìgbéraga ojú rẹ̀. 13 Nítorí ó sọ :

" Pẹ̀agbára ọwọ́ mi ni mo fi ṣe èyí

àti pẹ̀ọgbọ́n ̀n mi, nítorí mo òye.

Mo ààlà àwọn orílẹ̀-èdè kúrò,

mo ti ìṣúra wọn.

Gẹ́gẹ́ alágbára kan, mo borí àwọn ọba wọn.

14 ènìyàn ti í tọwọ́ bọ ìtẹ́ ẹyẹ,

bẹ́̀ ni ọwọ́ mi tẹ ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè.

ènìyàn ti í ẹyin a kọ̀sílẹ̀,

bẹ́̀ ni mo àwọn orílẹ̀-èdè

èyí ó fi apá lu apá,

tàbí ó ya ẹnu láti dún.’ "

15 Ǹjẹ́ àáké le gbé ara rẹ̀ sókè kọjá ẹni ó ń í,

tàbí ayùn fọ́nnu ẹni ó ń ó?

Àfi ẹni ̀ó na ẹni ó gbé e sókè,

tàbí kùmọ̀ lu èyí í ṣe igi.

16 Nítorí náà, ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

yóò rán ààrùn ìrẹ̀dànù sórí

àwọn akíkanjú jagunjagun,

lábẹ́ ògo rẹ̀ ni iná kan yóò ti sọ

gẹ́gẹ́ iná ajónirun.

17 Ìmọ́lẹ̀ Israẹli yóò di iná,

Ẹni Mímọ́ rẹ̀ yóò jẹ́ ̀wọ́-iná,

ọjọ́ kan ṣoṣo yóò yóò run

àti ̀gún àti ̀wọ̀n.

18 Gbogbo ẹwà igbó o rẹ̀, àti àwọn pápá ọlọ́ràá

gbogbo rẹ̀ ni yóò run pátápátá,

gẹ́gẹ́ ẹni ó ṣàìsàn ti í ṣòfò dànù.

19 Àwọn igi yóò nínú igbó o rẹ̀

yóò kéré níye,

̀dọ́mọdé yóò fi le kọ̀ wọ́n sílẹ̀.

Àwọn ìyókù Israẹli

20 ọjọ́ náà, àwọn ó ṣẹ́Israẹli,

àwọn ó ilé e Jakọbu,

gbẹ́kẹ̀ẹni náà

ó wọ́n bolẹ̀,

ṣùgbọ́n òtítọ́ yóò gbẹ́kẹ̀Olúwa,

Ẹni Mímọ́ Israẹli.

21 Àwọn ìyókù yóò padà, àwọn ìyókù ti Jakọbu

yóò padà ̀dọ̀ Ọlọ́run Alágbára.

22 ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ Israẹli dàbí yanrìn Òkun,

ẹni díẹ̀ ni yóò padà.

A ti pàṣẹ ìparun,

àkúnwọ́sílẹ̀ àti òdodo.

23 Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni yóò un ṣẹ,

ìparun a ti pàṣẹ rẹ̀ lórí gbogbo ilẹ̀ náà.

24 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ,

"̀yin ènìyàn mi ó ń gbé Sioni,

ṣe bẹ̀àwọn Asiria,

ó ń fi ̀yín,

wọ́n ń gbé ̀gọ yín

Ejibiti ti ṣe.

25 Láìpẹ́, ìbínú mi i yín yóò òpin

n ó dojú ìrunú mi kọ wọ́n, fún ìparun wọn."

26 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò wọ́n ẹgba.

Gẹ́gẹ́ ó ṣe lu Midiani òkè Orebu,

yóò gbé ̀rẹ̀ orí omi

gẹ́gẹ́ ó ti ṣe Ejibiti.

27 ọjọ́ náà, a ó gbé ẹrù wọn kúrò èjìká a yín,

àti àjàgà a wọn kúrò ọrùn un yín

a ó fọ́ àjàgà náà,

nítorí ̀yin ó ti sanra.

28 Wọ́n wọ Aiati,

wọ́n gba Migroni kọjá,

wọ́n nǹkan pamọ́ Mikmasi.

29 Wọ́n ti rékọjá ̀, wọ́n ,

"Àwa ó tẹ̀Geba lóru yìí."

Rama tìtì

Gibeah ti Saulu sálọ.

30 Gbé ohùn rẹ sókè, ìwọ ọmọbìnrin Galimu!

Dẹ etí sílẹ̀, ìwọ Laiṣa!

Ìwọ òtòṣì Anatoti!

31 Madmena ti fẹsẹ̀ fẹ́ ,

àwọn ènìyàn Gebimu ti fi ara pamọ́.

32 ọjọ́ yìí, wọn yóò dúró Nobu

wọn yóò kan sáárá,

òkè ọmọbìnrin Sioni

òkè Jerusalẹmu.

33 ó, Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

yóò kán ̀ka náà sọnù pẹ̀agbára.

Àwọn igi ọlọ́ni a ó lulẹ̀

àwọn ó ga gogoro ni a ó rẹ̀ sílẹ̀.

34 Òun yóò igbó dídí pẹ̀àáké,

Lebanoni yóò ṣubú níwájú Alágbára náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também