Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 14

1 Olúwa yóò fi àánú hàn fún Jakọbu,

yóò tún Israẹli yàn lẹ́̀kan i

yóò fi ìdí wọn kalẹ̀ ilẹ̀ àwọn tìkára wọn.

Àwọn àjèjì yóò darapọ̀ mọ́ wọn,

wọn yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀ilé e Jakọbu.

2 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbà wọ́n

wọn yóò wọn ààyè e wọn.

Ilé Israẹli yóò gba àwọn orílẹ̀-èdè

gẹ́gẹ́ àwọn ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin

ilẹ̀ Olúwa.

Wọn yóò àwọn akónilẹ́wọn ìgbèkùn

wọn yóò jẹ ọba lórí àwọn amúnisìn wọn.

3 ọjọ́ Olúwa yóò fi ìtura fún un yín kúrò nínú ìpọ́njú àti ìyà àti ìdè ìkà, 4 ó fi ̀rọ̀ àbùkù yìí kan ọba Babeli ,

báwo ni amúnisìn ṣe òpin!

Báwo ni ìbínú rẹ̀ ṣe parí!

5 Olúwa ti ̀ìkà náà,

̀àwọn aláṣẹ,

6 èyí ó ti lu àwọn ènìyàn bolẹ̀

pẹ̀ti dáwọ́ dúró,

nínú ìrunú ni ó ṣẹ́gun àwọn orílẹ̀-èdè

pẹ̀ìgbónára lópin.

7 Gbogbo ilẹ̀ ni ó ìsinmi àti àlàáfíà,

wọ́n orin.

8 Pẹ̀lúpẹ̀àwọn igi junifa àti àwọn

igi kedari ti Lebanoni

ń yọ̀ lórí rẹ ,

"Níwọ́n a ti rẹ̀ ́ sílẹ̀ báyìí,

agégi yóò láti wa lulẹ̀."

9 Ibojì ó ìsàlẹ̀ ni a ru sókè

láti pàdé rẹ ìpadàbọ̀ rẹ̀

ó ru ̀àwọn ó ti lọ sókè láti

gbogbo àwọn ó jẹ́ olórí ayé

ó wọn dìde lórí ìtẹ́ wọn

gbogbo àwọn ó jẹ ọba lórí àwọn orílẹ̀-èdè.

10 Gbogbo wọn yóò dáhùn,

wọn yóò fún ,

"Ìwọ pẹ̀ti di aláìlera, gẹ́gẹ́ àwa pẹ̀

ìwọ náà ti dàbí wa."

11 Gbogbo rẹ̀ ni ó di ìrẹ̀sílẹ̀ lọ ibojì,

pẹ̀ariwo àwọn dùùrù rẹ,

àwọn ìdin ni wọ́n fọ́nkálẹ̀ lábẹ́ rẹ

àwọn ekòló ti ́ mọ́lẹ̀.

12 Báwo ni ìwọ ṣe ṣubú lulẹ̀ láti ̀run ,

ìwọ ìràwọ̀ òwúrọ̀, ọmọ òwúrọ̀ náà!

A ti sọ ́ sílẹ̀ sínú ayé,

ìwọ o ti tẹ orí àwọn orílẹ̀-èdè ba !

13 Ìwọ sọ nínú ọkàn rẹ ,

"Èmi yóò gòkè lọ ̀run;

èmi yóò gbé ìtẹ́ mi sókè

ga ju àwọn ìràwọ̀ Ọlọ́run,

Èmi yóò gúnwà orí òkè àpéjọ

ṣóńṣó orí òkè mímọ́.

14 Èmi yóò gòkè lọ rékọjá àwọn àwọsánmọ̀;

èmi yóò ṣe ara mi gẹ́gẹ́ ̀gá-ògo."

15 Ṣùgbọ́n a ti rẹ̀ ́ sílẹ̀ wọ inú ibojì lọ

lọ ìsàlẹ̀ ̀gbun.

16 Àwọn ó yóò tẹjúmọ́ ,

wọ́n ronú nípa àtubọ̀tán rẹ:

"Ǹjẹ́ èyí ni ẹni ó mi ayé tìtì

ó jẹ́ àwọn ilẹ̀ ọba wárìrì.

17 Ẹni ó sọ ayé di aginjù,

ó pa ìlú ńlá ńlá rẹ̀ run

àwọn òǹdè rẹ̀ sílẹ̀ láti padà sílé?"

18 Gbogbo àwọn ọba orílẹ̀-èdè ni a tẹ́ sílẹ̀

̀kọ̀̀kan nínú ibojì tirẹ̀.

19 Ṣùgbọ́n a ́ síta kúrò nínú ibojì

gẹ́gẹ́ ̀ka igi a kọ̀sílẹ̀,

àwọn a pa ni ó ́ mọ́lẹ̀,

àwọn idà ti gún,

àwọn ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú òkúta inú ̀gbun.

Gẹ́gẹ́ òkú ó di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ abẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀,

20 a sin ́ pẹ̀wọn,

nítorí o ti ba ilẹ̀ rẹ jẹ́

o ti pa àwọn ènìyàn rẹ.

Ìran àwọn ìkà

ni a yóò dárúkọ wọn mọ́.

21 Tọ́ibìkan a ó ti pa àwọn ọmọkùnrin rẹ

nítorí ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá wọn,

wọn gbọdọ̀ dìde láti jogún ilẹ̀

wọ́n bo orí ilẹ̀ pẹ̀àwọn ìlú u wọn.

22 "Èmi yóò dìde sókè wọn,"

ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

"Èmi yóò orúkọ rẹ̀ kúrò Babeli àti àwọn ó sálà,

àwọn ọmọ àti ìran rẹ̀,"

ni Olúwa .

23 Èmi yóò i padà ibùgbé àwọn òwìwí

àti irà;

Èmi yóò fi ọwọ́ ìparun gbá a,

ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

Àsọtẹ́lẹ̀ lòdì Asiria

24 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra,

"Gẹ́gẹ́ mo ti ṣètò, bẹ́̀ ni yóò ,

àti mo ti pinnu, bẹ́̀ ni yóò dúró.

25 Èmi yóò run Asiria ilẹ̀ mi,

àwọn orí òkè mi ni èmi yóò ti rún un mọ́lẹ̀.

Àjàgà rẹ̀ ni a ó kúrò lọ́rùn àwọn ènìyàn mi,

ẹrù u rẹ̀ ni ó kúrò èjìká wọn."

26 Èyí ni ètò a pinnu rẹ̀ fún gbogbo ayé,

èyí ni ọwọ́ a jáde káàkiri gbogbo orílẹ̀-èdè.

27 Nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pète,

ta ni yóò a lọ́wọ́ ?

Ọwọ́rẹ ti jáde, ta ni ó le è á padà?

Àsọtẹ́lẹ̀ lòdì àwọn Filistini

28 ̀rọ̀-ìmọ̀ ọdún ọba Ahasi .

29 14.29-31: Jr 47; El 25.15-17; Jl 3.4-8; Am 1.6-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7. ṣe yọ̀, gbogbo ̀yin Filistia,

̀ó ́ ti ;

láti ibi gbòǹgbò ejò náà ni paramọ́lẹ̀

yóò ti jáde,

èso rẹ̀ yóò jẹ́ oró ejò í jóni.

30 Ẹni ó kúṣẹ̀́ yóò pápá oko,

àwọn aláìní yóò dùbúlẹ̀ láìléwu.

Ṣùgbọ́n gbòǹgbò o rẹ̀ ni èmi ó fi ìyàn parun,

yóò àwọn ẹni rẹ ó sálà kúrò.

31 Hu, ìwọ ẹnu-ọ̀! Kígbe, ìwọ ìlú!

Yọ́ kúrò, gbogbo ̀yin Filistia!

Èéfín kurukuru kan ti àríwá ,

ṣí amóríbọ́ kan nínú ẹgbẹ́ wọn.

32 ni ìdáhùn a ó fún

agbẹnusọ orílẹ̀-èdè náà?

"Olúwa ti fi ìdí Sioni kalẹ̀,

àti nínú rẹ̀ ni àwọn ènìyàn rẹ̀

a ti pọ́n ọn lójú yóò ti ààbò o wọn."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também