Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 36

Sennakeribu dẹ́rùba Jerusalẹmu

1 36.1–38.8,21-22: 2Ọb 18.13–20.11; 2Ki 32.1-24. ọdún kẹrìnlá ìjọba Hesekiah, Sennakeribu ọba Asiria kọlu gbogbo àwọn ìlú olódi ilẹ̀ Juda ó gbogbo wọn. 2 Lẹ́yìn náà, ọba Asiria rán olórí ogun rẹ̀ pẹ̀̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ-ogun láti Lakiṣi ọba Hesekiah Jerusalẹmu. Nígbà ̀gágun náà dúró níbi ojúṣàn adágún ti apá òkè, ojú ̀pápá alágbàfọ̀, 3 Ṣebna Eliakimu ọmọ Hilkiah alábojútó ààfin, Ṣebna akọ̀, àti Joah ọmọ Asafu akọ̀jáde lọ pàdé rẹ̀.

4 ̀gágun náà sọ fún wọn , "sọ fún Hesekiah,

" Èyí yìí ni ohun ọba ńlá, ọba Asiria sọ : Lórí i ni ìwọ gbé ìgbẹ́kẹ̀tìrẹ yìí ? 5 Ìwọ sọ ìwọ ète àti agbára ogunṣùgbọ́n ìwọ ń sọ ̀rọ̀ asán. Ta ni ìwọ gbẹ́kẹ̀ìwọ fi ṣọ̀tẹ̀ mi? 6 ó nísinsin yìí, ìwọ gbẹ́kẹ̀Ejibiti ̀rún igi ̀lásán í gún ni lọ́wọ́ í í dọ́gbẹ́ ni lára a gbára e! Bẹ́̀ ni Farao ọba Ejibiti àwọn ó gbẹ́kẹ̀e. 7 o sọ fún mi , "Àwa gbẹ́kẹ̀Olúwa Ọlọ́run wa," í ṣe òun ni Hesekiah ti àwọn ibi gíga àti pẹpẹ rẹ̀ kúrò, ó fún Juda àti Jerusalẹmu , "̀yin gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ yìí"?

8 " nísinsin yìí, ̀mi pa ìmọ̀ pọ̀, ọba Asiria, èmi yóò fún ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ẹṣin ìwọ le è fi agẹṣin wọn lórí! 9 Báwo ni ṣe ẹyọ kan ṣoṣo padà nínú èyí ó kéré nínú àwọn balógun olúwa mi, ó tilẹ̀ jẹ́ gbẹ́kẹ̀Ejibiti fún kẹ̀kẹ́-ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin? 10 Síwájú i, ǹjẹ́ mo wa ilẹ̀ yìí n pa á run láìsí Olúwa? Olúwa fún rara rẹ̀ sọ n orílẹ̀-èdè yìí n pa á run.’ "

11 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu, Ṣebna àti Joah sọ fún ̀gágun náà , "Jọ̀wọ́ máa àwọn ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀ èdè Aramaiki, nítorí àwa gbọ́ . ṣe wa sọ̀rọ̀ èdè Heberu etí àwọn ènìyàn ó lórí ògiri mọ́."

12 Ṣùgbọ́n aláṣẹ dáhùn , "Ṣé fún ̀rẹ àti ìwọ nìkan ̀mi rán mi láti sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí í í ṣe fún àwọn ọkùnrin ó jókòó lórí odi ni gẹ́gẹ́ ìwọ, ni yóò láti jẹ ìgbẹ́ ará wọn wọ́n mu ìtọ̀ ará wọn?"

13 Lẹ́yìn náà ni ̀gágun náà dìde ó síta èdè Heberu , "gbọ́ àwọn ̀rọ̀ ọba ńlá, ọba Asiria! 14 Ohun ọba nìyìí, ṣe jẹ́ Hesekiah tàn yín jẹ. Òun le è gbà yín sílẹ̀! 15 ṣe jẹ́ Hesekiah rọ̀ yín láti gbẹ́kẹ̀Olúwa nígbà ó sọ , Olúwa yóò kúkú gbà ; a yóò fi ìlú yìí ọba Asiria lọ́wọ́.’

16 "ṣe tẹ́Hesekiah. Ohun ọba Asiria nìyìí. fi ̀bùn mi rẹ́, jáde tọ̀ . Lẹ́yìn náà, ẹnìkọ̀̀kan yín yóò jẹ nínú àjàrà àti igi ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ bẹ́̀ ni yóò mu omi nínú kànga rẹ̀, 17 títí èmi yóò fi un yín lọ ilẹ̀ kan ó dàbí i tiyín, ilẹ̀ ó irúgbìn oníhóró àti wáìnì tuntun, ilẹ̀ ó àkàrà àti ọgbà àjàrà.

18 "ṣe jẹ́ Hesekiah ṣì yín lọ́nígbà ó sọ , Olúwa yóò gbà .Ǹjẹ́ ọlọ́run orílẹ̀-èdè kan ha ti gbà á kúrò lọ́wọ́ ọba Asiria ? 19 Níbo ni àwọn òrìṣà Hamati àti Arpadi ha ? Níbo ni àwọn òrìṣà Sefarfaimi ha ? Ǹjẹ́ wọn ti Samaria gbà kúrò lọ́wọ́ mi ? 20 Èwo nínú àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ha ti dáàbò bo ilẹ̀ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi? Báwo ni Olúwa ṣe le gba Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ mi?"

21 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà dákẹ́ rọ́rọ́ wọn èsì kankan , nítorí ọba ti pàṣẹ fún wọn , "ṣe a lóhùn."

22 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu ọmọ Hilkiah alákòóso ààfin, Ṣebna akọ̀àti Joah ọmọ Asafu akọ̀àkọsílẹ̀ lọ ̀dọ̀ Hesekiah pẹ̀aṣọ wọn fífàya, wọ́n sọ ohun ̀gágun ti .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também