Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 34

Ìdájọ́ Ọlọ́run lòdì àwọn orílẹ̀-èdè

1 34.1-17: Isa 63.1-6; Jr 49.7-22; El 25.12-14; 35; Am 1.11-12; Od 1-14; Ml 1.2-5. Súnmọ́ tòsí,

̀yin orílẹ̀-èdè láti gbọ́,

tẹ́sílẹ̀ ̀yin ènìyàn

jẹ́ ayé gbọ́,

àti ̀kún rẹ̀,

ayé àti ohun gbogbo ó ti inú rẹ̀ jáde.

2 Nítorí ìbínú Olúwa ń bẹ

lára gbogbo orílẹ̀-èdè,

àti ìrunú rẹ̀ lórí gbogbo ogun wọn:

o ti fi wọ́n fún pípa.

3 Àwọn ti a pa nínú wọn

ni a ó sóde,

òórùn wọn yóò ti inú òkú wọn jáde,

àwọn òkè ńlá yóò yọ̀ nínú ̀jẹ̀ wọn.

4 34.4: If 6.13-14. Gbogbo àwọn ogun ̀run ni yóò di yíyọ́,

a ó àwọn ̀run jọ i tákàdá,

gbogbo ogun wọn yóò si ṣubú lulẹ̀,

ewé ti n bọ́ kúrò lára àjàrà,

àti i bíbọ́ èso lára igi ̀pọ̀tọ́.

5 Nítorí ti a rẹ idà mi ̀run,

kíyèsi í, yóò sọ̀kalẹ̀ sórí Edomu,

sórí àwọn ènìyàn mo ti parun fún ìdájọ́.

6 Idà Olúwa kún fún ̀jẹ̀

a un sanra fún ̀,

àti fún ̀jẹ̀ ̀dọ́-àgùntàn àti ewúrẹ́,

fún ̀ìwé àgbò

nítorí Olúwa ni ìrúbọ kan Bosra,

àti ìpakúpa ńlá kan ilẹ̀ Edomu.

7 Àti àwọn àgbáǹréré yóò

ba wọn sọ̀kalẹ̀ ,

àti àwọn ẹgbọrọ màlúù

pẹ̀àwọn akọ màlúù,

ilé wọn ni a ó fi ̀jẹ̀ rin,

a ó fi ̀sọ ekuru wọn di ọlọ́ràá.

8 Nítorí ọjọ́ ̀san Olúwa ni,

àti ọdún ìsanpadà,

nítorí ̀ràn Sioni.

9 34.9-10: If 19.3. Odò rẹ̀ ni a ó sọ di ̀,

àti eruku rẹ̀ di imí-ọjọ́,

ilẹ̀ rẹ̀ yóò di ̀ń jóná.

10 A yóò pa á òru tàbí ̀sán;

èéfín rẹ̀ yóò gòkè láéláé:

yóò dahoro láti ìran ìran,

ẹnìkan yóò á kọjá láé àti láéláé.

11 Òwìwí aginjù, àti àkàlà ni yóò ni ín,

àti òwìwí àti ẹyẹ ìwò ni yóò máa gbé inú rẹ̀.

Ọlọ́run yóò na sórí Edomu

okùn ìwọ̀n ìparun

àti òkúta òfo.

12 ti àwọn ìjòyè rẹ̀

ẹnìkan yóò níbẹ̀

tiwọn ó ìjọba,

gbogbo àwọn olórí i rẹ̀ yóò di asán.

13 ̀gún yóò jáde

nínú àwọn ààfin rẹ̀ wọ̀nyí,

̀gún ̀gán nínú ìlú olódi rẹ̀.

Yóò jẹ́ ibùgbé àwọn akátá

àti àgbàlá fún àwọn òwìwí.

14 Àwọn ẹranko ijù àti àwọn ìkookò ni yóò pàdé,

àti ewúrẹ́ igbó kan yóò máa kọ èkejì rẹ̀,

iwin yóò máa gbé ibẹ̀ pẹ̀,

yóò ibi ìsinmi fún ara rẹ̀.

15 Òwìwí yóò tẹ́ ìtẹ́ rẹ̀ síbẹ̀,

yóò , yóò pa,

yóò kójọ lábẹ́ òjìji rẹ̀:

àwọn gúnnugún yóò péjọ síbẹ̀ pẹ̀,

olúkúlùkù pẹ̀ẹnìkejì rẹ̀.

16 wo ìwé Olúwa, .

̀kan nínú ìwọ̀nyí yóò yẹ̀,

̀kan yóò fẹ́ èkejì rẹ̀ :

nítorí Olúwa ti pàṣẹ

ẹnu rẹ̀ fi wọn jọ

̀rẹ̀ fi wọ́n jọ.

17 Ó ti di ìbò fún wọn,

ọwọ́ rẹ̀ ti pín in fún wọn

nípa títa okùn,

wọn ó jogún rẹ̀ láéláé,

láti ìran ìran

ni wọn ó máa gbé inú rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também