Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 37

A sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ìdáǹdè Jerusalẹmu

1 Nígbà ọba Hesekiah gbọ́ èyí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó fi aṣọ ̀fọ̀ bo ara rẹ̀, ó wọ inú tẹmpili Olúwa lọ. 2 Òun rán Eliakimu alákòóso ààfin, Ṣebna akọ̀, àti aṣíwájú àwọn àlùfáà, gbogbo wọn nínú aṣọ ̀fọ̀ lọ ̀dọ̀ wòlíì Isaiah ọmọ Amosi. 3 Wọ́n sọ fún un , "Báyìí ni Hesekiah , ọjọ́ òní jẹ́ ọjọ́ ìbànújẹ́, ìbáwí àti ̀gàn gẹ́gẹ́ ìgbà ìbí àwọn ọmọdé ṣí agbára láti wọn. 4 Ó jẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbọ́ ̀rọ̀ ̀gágun ẹni ̀rẹ̀ ọba Asiria ti rán láti fi Ọlọ́run alààyè ṣe ẹlẹ́, àti òun ni yóò a nítorí àwọn ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ ti gbọ́. Nítorí náà gbàdúrà fún àwọn ó ṣẹ́wọ́n láààyè."

5 Nígbà àwọn ìjòyè ọba Hesekiah ̀dọ̀ Isaiah, 6 Isaiah sọ fún wọn , "sọ fún ̀yín , Ohun Olúwa sọ nìyìí. ṣe bẹ̀ohun ti gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ ọba Asiria ó nínú ìdè ti fi sọ̀rọ̀-òdì mi. 7 Tẹ́sílẹ̀! Èmi yóò fi ̀kan sínú rẹ̀ bẹ́̀ ó fi jẹ́ o ti gbọ́ ìròyìn kan, òun yóò padà orílẹ̀-èdè rẹ̀, níbẹ̀ ni n ó ti jẹ́ wọn e lulẹ̀ pẹ̀idà.’ "

8 Nígbà ̀gágun gbọ́ ọba Asiria ti fi Lakiṣi sílẹ̀, ó padà sẹ́yìn, ó ọba ń Libina .

9 àkókò yìí Sennakeribu gbọ́ ìròyìn kan Tirakah ará Kuṣi ọba Ejibiti ń jáde bọ̀ òun . Nígbà ó gbọ́ èyí, ó rán oníṣẹ́ Hesekiah pẹ̀̀rọ̀ wọ̀nyí, 10 "sọ fún Hesekiah ọba Juda : ṣe jẹ́ òrìṣà ìwọ gbẹ́kẹ̀tàn ́ jẹ nígbà ó sọ , A yóò jọ̀wọ́ Jerusalẹmu fún ọba Asiria.11 Dájúdájú, ìwọ ti gbọ́ ohun ọba Asiria ti ṣe àwọn orílẹ̀-èdè, ó pa wọ́n run pátápátá. Ǹjẹ́ a ó ha nídè ? 12 Ǹjẹ́ àwọn òrìṣà àwọn orílẹ̀-èdè àwọn baba ńlá mi parun ha gbà wọ́n sílẹ̀ àwọn òrìṣà Gosani, Harani, Reṣefu àti àwọn ènìyàn Edeni wọ́n Teli-Assari? 13 Níbo ni ọba Hamati , ọba Arpadi, ọba ìlú Sefarfaimi tàbí Hena tàbí Iffa?"

Àdúrà Hesekiah

14 Hesekiah gba ìwé náà lọ́wọ́ àwọn oníṣẹ́ ó á. Lẹ́yìn náà ni ó gòkè lọ tẹmpili Olúwa ó tẹ́ ìwé náà sílẹ̀ níwájú Olúwa. 15 Hesekiah gbàdúrà Olúwa: 16 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli, ó gúnwà láàrín àwọn kérúbù, ìwọ nìkan ni Ọlọ́run lórí i gbogbo ìjọba orílẹ̀ ayé. Ìwọ ti ̀run àti ayé. 17 Tẹ́sílẹ̀, ìwọ Olúwa, o gbọ́, ya ojú rẹ, Ìwọ Olúwa, o i; tẹ́gbogbo ̀rọ̀ Sennakeribu rán láti fi àbùkù kan Ọlọ́run alààyè.

18 "Òtítọ́ ni Olúwa àwọn ọba Asiria ti sọ àwọn ènìyàn àti ilẹ̀ wọn di asán. 19 Wọ́n ti da àwọn òrìṣà wọn sínú iná wọ́n ti pa wọ́n run, nítorí àwọn wọ̀nyí í ṣe ọlọ́run ṣe igi àti òkúta lásán, a ti ọwọ́ ènìyàn ṣe. 20 Nísinsin yìí, ìwọ Olúwa, Ọlọ́run wa, gbà lọ́wọ́ rẹ̀, ó fi jẹ́ gbogbo ìjọba ilẹ̀ ayé yóò fi mọ̀ Ìwọ, Ìwọ nìkan, Olúwa ni Ọlọ́run."

Ìṣubú Sennakeribu

21 Lẹ́yìn náà Isaiah ọmọ Amosi rán iṣẹ́ kan Hesekiah: "Èyí ni ohun Olúwa, Ọlọ́run Israẹli sọ , nítorí ìwọ ti gbàdúrà mi nípa Sennakeribu ọba Asiria, 22 èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ti sọ nípa rẹ̀:

"Wúńdíá ọmọbìnrin Sioni

ti kẹ́gàn rẹ, ó ti fi ṣe ẹlẹ́.

Ọmọbìnrin Jerusalẹmu

ti mi orí rẹ̀ ó ti ń sálọ.

23 Ta ni ìwọ ti ìwọ ti sọ̀rọ̀-òdì ?

ta ìwọ ti gbé ohùn rẹ sókè

o gbé ojú rẹ sókè ìgbéraga?

Ẹni Mímọ́ Israẹli!

24 Nípa àwọn ìránṣẹ́ rẹ,

ìwọ ti sọ̀rọ̀ búburú Olúwa.

wọ ,

Pẹ̀̀pọ̀ kẹ̀kẹ́ mi

ni èmi fi orí àwọn òkè ńlá,

ibi gíga jùlọ Lebanoni.

Èmi a igi kedari gíga rẹ̀ lulẹ̀,

àti ààyò igi firi rẹ̀.

Èmi ti ibi rẹ̀ ó ga jùlọ,

igbó rẹ̀ ó dára jùlọ.

25 Èmi ti gbẹ́ kànga ilẹ̀ àjèjì

mo mu omi ibẹ̀,

pẹ̀àtẹ́lẹsẹ̀ mi

Èmi ti gbẹ́ gbogbo omi àwọn odò Ejibiti.

26 "Ṣé o ì gbọ́?

Tipẹ́tipẹ́ ni mo ti fìdí rẹ̀ mulẹ̀.

Láti ìgbà pípẹ́ ni mo ti ṣètò rẹ̀;

àkókò yìí ni mo ìmúṣẹ,

o ti sọ àwọn ìlú olódi di

àkójọpọ̀ àwọn òkúta.

27 Àwọn ènìyàn, agbára ti wọ̀ lẹ́,

ni wọ́n banújẹ́ a dójútì.

Wọ́n dàbí ohun ̀gbìn nínú pápá,

gẹ́gẹ́ ̀jẹ̀lẹ̀ èhíhù tuntun,

gẹ́gẹ́ i koríko ó ń lórí òrùlé,

ó jóná ó dàgbàsókè.

28 "Ṣùgbọ́n mo mọ ibi o

àti ìgbà o o lọ

àti inú rẹ ṣe ru mi.

29 Nítorí inú rẹ ru mi

àti nítorí orí kunkun rẹ ti

etí ìgbọ́ mi,

Èmi yóò fi ìwọ̀ mi imú,

àti ìjẹ mi lẹ́nu,

èmi yóò jẹ́ o padà

láti ̀o gbà .

30 "Èyí ni yóò ṣe àmì fún , ìwọ Hesekiah:

"ọdún yìí, ìwọ yóò jẹ ohun ó fúnra rẹ̀,

àti ọdún kejì ohun ó jáde láti ara rẹ.

Ṣùgbọ́n ọdún kẹta, gbìn kórè,

gbin ọgbà àjàrà jẹ èso wọn.

31 Lẹ́̀kan i, àṣẹ́láti ilé Juda

yóò ta gbòǹgbò nísàlẹ̀ yóò ṣo èso lókè.

32 Nítorí láti Jerusalẹmu ni àwọn àṣẹ́yóò ti ,

àti láti òkè Sioni ni ikọ̀ àwọn ó sálà.

Ìtara Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni yóò èyí ṣẹ.

33 "Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa nípa ọba Asiria,

"Òun yóò wọ ìlú yìí

tàbí ta ẹyọ ọfà kan níhìn-ín

Òun yóò síwájú rẹ pẹ̀asà

tàbí ó dágunró sílẹ̀ fún un.

34 Nípa ̀ó gbà náà ni yóò padà lọ;

òun yóò wọ inú ìlú yìí,"

ni Olúwa .

35 "Èmi yóò dáàbò bo ìlú yìí èmi ó gbà á ,

nítorí mi àti nítorí Dafidi ìránṣẹ́ mi!"

36 Lẹ́yìn náà ni angẹli Olúwa jáde lọ ó pa ̀kẹ́ mẹ́sàn-án ó ẹgbẹ̀́dọ́gbọ̀n (185,000) ènìyàn i ibùdó àwọn Asiria. Nígbà àwọn ènìyàn yìí òwúrọ̀ ọjọ́ kejì gbogbo wọn ti dòkú! 37 Nítorí náà Sennakeribu ọba Asiria fọ́ bùdó ó pẹsẹ̀. Òun padà Ninefe, ó dúró síbẹ̀.

38 ọjọ́ kan, ó ti ń jọ́sìn nínú tẹmpili Nisroki òrìṣà rẹ̀, àwọn ọmọ rẹ̀ Adrameleki àti Ṣareseri e lulẹ̀ pẹ̀idà, wọ́n sálọ ilẹ̀ Ararati. Bẹ́̀ ni Esarhadoni ọmọ rẹ̀ gba ipò rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também