Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 19

Àsọtẹ́lẹ̀ lòdì Ejibiti

1 19.1-25: Jr 46; El 29–32; Sk 14.18-19. ̀rọ̀-ìmọ̀ ó kan Ejibiti.

Kíyèsi i, Olúwa gun àwọsánmọ̀ ó yára lẹ́ṣin

ó ń bọ̀ Ejibiti.

Àwọn ère òrìṣà Ejibiti wárìrì níwájú rẹ̀,

ọkàn àwọn ará Ejibiti ti domi nínú wọn.

2 "Èmi yóò àwọn ará Ejibiti sókè ara wọn

arákùnrin yóò arákùnrin rẹ̀ ,

aládùúgbò yóò dìde aládùúgbò rẹ̀,

ìlú yóò dìde ìlú,

ilẹ̀ ọba ilẹ̀ ọba.

3 Àwọn ará Ejibiti yóò sọ ìrètí ,

èmi yóò sọ èrò wọn gbogbo di òfo;

wọn yóò àwọn òrìṣà àti ̀àwọn òkú sọ̀rọ̀,

àwọn awoṣẹ́ àti àwọn abókùúsọ̀rọ̀.

4 Èmi yóò fi Ejibiti agbára

àwọn ìkà amúnisìn lọ́wọ́,

ọba aláìláàánú ni yóò jẹ ọba wọn lórí,"

ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

5 Gbogbo omi inú odò ni yóò gbẹ,

gbogbo ilẹ̀ àyíká odò ni yóò gbẹ yóò sáàpá.

6 Adágún omi yóò di rírùn;

àwọn odò ilẹ̀ Ejibiti yóò máa dínkù

wọn yóò gbẹ.

Àwọn koríko odò àti ìrẹ̀tẹ̀ yóò gbẹ,

7 àwọn igi ipadò Naili pẹ̀,

ó orísun odò,

gbogbo oko a ipadò Naili

yóò gbẹ dànù yóò fẹ́ dànù

mọ́.

8 Àwọn apẹja yóò sọkún kíkorò,

àti gbogbo àwọn ó ń ju ìwọ̀ sínú odò;

odò náà yóò máa rùn.

9 Àwọn ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀̀gbọ̀ yóò kọminú

àwọn ahunṣọ ̀gbọ̀ yóò sọ ìrètí .

10 Àwọn ń ṣiṣẹ́ aṣọ yóò rẹ̀wẹ̀,

gbogbo àwọn oníṣẹ́ oṣù ni àìsàn ọkàn yóò ṣe.

11 Àwọn oníṣẹ́ Ṣoani ti di aláìgbọ́n,

àwọn ọlọ́gbọ́n olùdámọ̀ràn Farao

ń ìmọ̀ràn àìgbọ́n .

Báwo ṣe sọ fún Farao ,

"Mo jẹ́ ̀kan nínú àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn,

̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn ọba àtijọ́."

12 Níbo ni àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn rẹ báyìí?

Jẹ́ wọn fihàn ́ wọn sọ ́ di mọ̀

ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ti pinnu lórí Ejibiti.

13 Àwọn ọmọ-aládé Ṣoani ti di aṣiwèrè,

a ti tan àwọn ọmọ-aládé Memfisi jẹ;

àwọn òkúta igun ilé í ṣe ti ̀rẹ

ti ṣi Ejibiti lọ́.

14 Olúwa ti da ̀òòyì sínú wọn;

wọ́n Ejibiti ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú

ohun gbogbo ó ń ṣe,

gẹ́gẹ́ ̀mùtí ti í ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú èébì rẹ̀.

15 ohun Ejibiti le ṣe

orí tàbí ìrù, ̀̀pẹ tàbí koríko odò.

16 ọjọ́ náà ni àwọn ará Ejibiti yóò dàbí obìnrin. Wọn yóò gbọ̀n jìnnìjìnnì pẹ̀̀nítorí ọwọ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun a gbé sókè wọn. 17 Ilẹ̀ Juda yóò di ̀fún Ejibiti; gbogbo àwọn a ti dárúkọ Juda létí wọn ni yóò wárìrì, nítorí ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbèrò láti ṣe wọn.

18 ọjọ́ náà ìlú márùn-ún ilẹ̀ Ejibiti yóò sọ èdè àwọn ará Kenaani, wọn yóò búra àtìlẹ́yìn fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun. ̀kan nínú wọn ni a ó máa ìlú ìparun.

19 ọjọ́ náà pẹpẹ kan yóò fún Olúwa àárín gbùngbùn Ejibiti, àti ̀wọ́n kan fún Olúwa etí bodè rẹ̀. 20 Yóò jẹ́ àmì àti ̀Olúwa àwọn ọmọ-ogun ilẹ̀ Ejibiti. Nígbà wọ́n pe Olúwa nítorí àwọn aninilára wọn, yóò rán olùgbàlà àti olùgbèjà kan wọn yóò gbà wọ́n sílẹ̀. 21 Báyìí ni Olúwa yóò sọ ara rẹ̀ di mọ̀ fún àwọn ará Ejibiti àti ọjọ́ náà ni wọn yóò gba Olúwa gbọ́. Wọn yóò sìn ín pẹ̀ẹbọ ọrẹ ìyẹ̀fun, wọn yóò jẹ́ ̀jẹ́ fún Olúwa wọn yóò un ṣẹ. 22 Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn kan Ejibiti ; yóò wọn yóò tún wọ́n sàn. Wọn yóò yípadà Olúwa, Òun yóò gbọ́ ̀bẹ̀ wọn yóò wọ́n sàn.

23 ọjọ́ náà òpópónà kan yóò láti Ejibiti lọ Asiria. Àwọn ará Asiria yóò lọ Ejibiti àti àwọn ará Ejibiti lọ Asiria. Àwọn ará Ejibiti àti ará Asiria yóò jọ́sìn papọ̀. 24 ọjọ́ náà Israẹli yóò di ̀kẹta pẹ̀Ejibiti àti Asiria, àní orísun ìbùkún ilẹ̀ ayé. 25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò bùkún wọn yóò , "Ìbùkún ni fún Ejibiti ènìyàn mi, Asiria iṣẹ́ ọwọ́ mi, àti Israẹli ìní mi."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também