Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 33

Elihu Jobu sọ̀rọ̀

1 "Ǹjẹ́ nítorí náà, Jobu, èmí bẹ̀ ,

gbọ́ ̀rọ̀ mi o fetísí ̀rọ̀ mi!

2 Kíyèsi i nísinsin yìí, èmí ya ẹnu mi,

ahọ́n mi sọ̀rọ̀ ẹnu mi.

3 ̀rọ̀ mi yóò jásí ìdúró ṣinṣin ọkàn mi,

ètè mi yóò sọ ìmọ̀ mi jáde dájúdájú.

4 ̀Ọlọ́run ni ó mi,

àti ìmísí Olódùmarè ni ó ti fún mi ìyè.

5 ìwọ le mi lóhùn,

̀rọ̀ rẹ̀ lẹ́sẹẹsẹ níwájú mi;

6 kíyèsi i, ìwọ ṣe jẹ́ ti Ọlọ́run, bẹ́̀ ni èmi náà;

láti amọ̀ ni a ti mi pẹ̀.

7 Kíyèsi i, ̀ńlá mi yóò ;

bẹ́̀ ni ọwọ́ mi yóò wúwo lára.

8 "Nítòótọ́ ìwọ sọ etí mi,

èmí gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀ ,

9 Èmi mọ́, láìní ìrékọjá, aláìṣẹ̀ èmi;

bẹ́̀ àìṣedéédéé ọwọ́ mi.

10 Kíyèsi i, Ọlọ́run ti àìṣedéédéé pẹ̀mi;

ó ̀rẹ̀.

11 Ó kan ̀ṣẹ̀ mi sínú àbà;

o kíyèsi ipa ̀mi gbogbo.

12 "Kíyèsi i, nínú èyí ìwọ ṣìnà!

Èmi ó lóhùn , Ọlọ́run tóbi ènìyàn lọ!

13 Nítorí ni ìwọ ṣe ń a , ,

òun sọ ̀rọ̀ kan nítorí iṣẹ́ rẹ̀?

14 Nítorí pe Ọlọ́run sọ̀rọ̀ lẹ́̀kan,

àní, lẹ́̀kejì, ṣùgbọ́n ènìyàn róye rẹ̀.

15 Nínú àlá, ojúran òru,

nígbà orun èjìká kùn ènìyàn lọ,

sísùn lórí ibùsùn,

16 nígbà náà ni ó sọ̀rọ̀ etí wọn,

yóò dẹ́rùbà wọ́n pẹ̀ìbáwí,

17 ó fa ènìyàn sẹ́yìn kúrò nínú ètè rẹ̀;

ó pa ìgbéraga mọ́ kúrò lọ́dọ̀ ènìyàn;

18 Ó fa ọkàn rẹ̀ padà kúrò nínú isà òkú,

àti ̀rẹ̀ láti ṣègbé lọ́wọ́ idà.

19 "A án lórí ibùsùn ìrora rẹ̀;

pẹ̀lúpẹ̀a fi ìjà egungun rẹ̀ ti ó dúró pẹ́ án,

20 bẹ́̀ ni ̀rẹ kọ oúnjẹ,

ọkàn rẹ̀ kọ oúnjẹ dídùn.

21 Ẹran-ara rẹ̀ run, títí a fi i mọ́

egungun rẹ̀ a ta jáde.

22 Àní, ọkàn rẹ̀ súnmọ́ isà òkú,

̀rẹ̀ súnmọ́ ̀dọ̀ àwọn ìránṣẹ́ ikú.

23 angẹli kan ba lọ́dọ̀ rẹ̀,

ẹni ń ṣe alágbàwí,

̀kan nínú ẹgbẹ̀rún (1,000) láti fi ̀pípé hàn ni,

24 nígbà náà ni ó ṣe oore-ọ̀fẹ́ fún un ó ,

gbà á kúrò nínú lílọ sínú isà òkú;

èmi ti á padà.

25 Ara rẹ̀ yóò di ̀tun i ti ọmọ kékeré,

yóò tún padà ọjọ́ ìgbà èwe rẹ̀;

26 Ó gbàdúrà sọ́dọ̀ Ọlọ́run, òun ṣe ojúrere rẹ̀,

o ojú rẹ̀ pẹ̀ayọ̀,

òhun o san òdodo rẹ̀ padà fún ènìyàn.

27 Ó sọ́dọ̀ ènìyàn ó ,

Èmi ṣẹ̀, ṣí èyí o tọ́, mo ti èyí ó tọ́ po,

a san ̀san rẹ̀ fún mi;

28 Ọlọ́run ti gba ọkàn mi kúrò nínú lílọ sínú ihò,

̀mi yóò láti jẹ adùn ìmọ́lẹ̀ ayé.

29 "ó! Nǹkan wọ̀nyí ni Ọlọ́run

máa ń ṣe fún ènìyàn nígbà méjì àti nígbà mẹ́ta,

30 láti ọkàn rẹ padà kúrò nínú isà òkú,

láti fi ìmọ́lẹ̀ alààyè han i.

31 "Jobu, kíyèsi i gidigidi, o fetí mi;

pa ẹnu rẹ mọ́, èmi ó máa sọ ́.

32 ìwọ ohun , mi lóhùn;

máa sọ, nítorí èmi fẹ́ láre.

33 bẹ́̀ kọ́, gbọ́ tèmi;

pa ẹnu rẹ mọ́, èmi ó kọ́ ọgbọ́n."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também