Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 36

1 Elihu tún sọ̀rọ̀ ,

2 "Fún mi láyè díẹ̀ èmi ó fihàn ́,

nítorí ̀rọ̀ sísọ ó kún fún Ọlọ́run.

3 Èmi ó ìmọ̀ mi ti ̀jíjìn ,

èmi ó fi òdodo fún Ẹlẹ́dàá mi.

4 i dájú ̀rọ̀ mi yóò ṣèké nítòótọ́;

ẹni ó ìmọ̀ pẹ̀rẹ̀.

5 "Kíyèsi i, Ọlọ́run ni alágbára, òun i gàn ènìyàn;

ó agbára ipá àti òye.

6 Òun í ̀ènìyàn búburú ,

ṣùgbọ́n ó fi òtítọ́ fún àwọn tálákà.

7 Òun í ojú rẹ̀ kúrò lára olódodo,

ṣùgbọ́n àwọn ọba ni wọ́n lórí ìtẹ́;

àní ó fi ìdí wọn múlẹ̀ láéláé, a gbé wọn lékè.

8 ó wọ́n nínú àbà,

a fi okùn ìpọ́njú wọ́n,

9 nígbà náà ni ó ń sọ àwọn ohun wọn ti ṣe fún wọn,

wọ́n ti ṣẹ̀ pẹ̀ìgbéraga wọn.

10 Ó wọn létí pẹ̀̀̀kọ́,

ó pàṣẹ wọn ó padà kúrò nínú àìṣedédé.

11 wọ́n gbàgbọ́ wọ́n sìn ín,

wọn ó lo ọjọ́ wọn ìrọ̀rùn,

àti ọdún wọn nínú afẹ́.

12 Ṣùgbọ́n, wọn gbàgbọ́,

wọ́n ó ti ọwọ́ idà ṣègbé,

wọ́n á láìní òye.

13 "Ṣùgbọ́n àwọn àgàbàgebè ayé ìbínú jọ;

wọn kígbe fún ìrànlọ́wọ́ nígbà ó wọ́n .

14 Nígbà náà ni ọkàn wọn yóò èwe,

àárín àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà.

15 Òun gba òtòṣì nínú ìpọ́njú wọn,

a sọ̀rọ̀ wọn etí nínú ìnira wọn.

16 "Bẹ́̀ ni pẹ̀lúpẹ̀ó fa wọn yọ láti inú ìhágágá ibi gbòòrò,

ibi ó ààyè wàhálà nínú rẹ̀,

ohun a gbé kalẹ̀ tábìlì rẹ̀ jẹ́ kìkì ̀oúnjẹ ó fẹ́.

17 Ṣùgbọ́n ìwọ kún fún ìdájọ́ àwọn búburú;

ìdájọ́ àti òtítọ́ ́ .

18 Nítorí ìbínú ń bẹ, ṣọ́ra òtítọ́ rẹ máa a tàn ;

láti jẹ́ títóbi rẹ ṣìnà.

19 Ọrọ̀ rẹ pọ̀ , wàhálà yóò fi ?

Tàbí ipa agbára rẹ?

20 ṣe ìfẹ́ òru, nígbà a ń

àwọn orílẹ̀-èdè kúrò ipò wọn.

21 Máa ṣọ́ra ìwọ ki ó ara rẹ̀ padà búburú,

nítorí èyí ìwọ ó dára ìpọ́njú lọ.

22 "Kíyèsi i, Ọlọ́run ni gbéga nípa agbára rẹ̀;

ta ni jẹ́ olùkọ́ni rẹ̀?

23 Ta ni ó ̀iṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ fún un,

tàbí ta ni ó ìwọ ti ń ṣe àìṣedéédéé?

24 Rántí ìwọ ó gbé iṣẹ́ rẹ̀ ga,

ti ènìyàn ni yín nínú orin.

25 Olúkúlùkù ènìyàn a máa i;

ẹni ikú a máa ó òkèrè.

26 Kíyèsi i, Ọlọ́run tóbi, àwa mọ̀ ó ti òye ,

bẹ́̀ ni a wádìí iye ọdún rẹ̀ .

27 "Nítorí òun ni ó fa ìkán omi òjò sílẹ̀,

wọn ó kán òjò ìkùùkuu rẹ̀,

28 àwọsánmọ̀ ń rọ̀ ìrì rẹ̀ sílẹ̀,

ó fi ń sẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ lórí ènìyàn.

29 Pẹ̀lúpẹ̀ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni ìmọ̀ ìtànká àwọsánmọ̀,

tàbí ariwo àrá láti àgọ́ rẹ̀?

30 Kíyèsi i, ó tan ìmọ́lẹ̀ ara rẹ̀

ó bo ìsàlẹ̀ òkun mọ́lẹ̀.

31 Nítorí nípa wọn ń ṣe dájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ènìyàn;

ó ń pèsè oúnjẹ ̀pọ̀lọpọ̀.

32 Ó fi ìmọ́lẹ̀ bo ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì

ó rán an ẹni olódì.

33 Ariwo àrá rẹ̀ fi ìjì hàn ;

̀wọ́ ẹran pẹ̀, ó súnmọ́ etílé!

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também