Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 8

Bilidadi

1 Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn ,

2 "Ìwọ yóò ti máa sọ nǹkan wọ̀nyí pẹ́ ?

̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ yóò máa ̀fúùfù ńlá?

3 Ọlọ́run a ha máa ìdájọ́ po ?

Tàbí Olódùmarè a máa gbé ̀bi fún aláre?

4 Nígbà àwọn ọmọ rẹ̀ ṣẹ̀ i,

ó gbá wọn kúrò nítorí ìrékọjá wọn.

5 ìwọ pe Ọlọ́run àkókò,

ìwọ gbàdúrà ̀bẹ̀ Olódùmarè.

6 Ìwọ ìbá jẹ́ mímọ, ó dúró ṣinṣin:

ǹjẹ́ nítòótọ́ nísinsin yìí òun yóò tají fún ,

òun a sọ ibùjókòó òdodo rẹ di púpọ̀.

7 Ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ ìbá tilẹ̀ kéré si í,

bẹ́̀ ìgbẹ̀yìn rẹ ìbá pọ̀ i gidigidi.

8 "Èmi bẹ̀ ́ ǹjẹ́, béèrè lọ́wọ́ àwọn ará ìgbà

o kíyèsi ìwádìí àwọn baba wọn.

9 Nítorí ọmọ-àná ni àwa, a mọ nǹkan,

nítorí òjìji ni ọjọ́ wa ni ayé.

10 Àwọn yóò wa kọ ́, wọn yóò sọ fún ?

Wọn yóò sọ̀rọ̀ láti inú òye wọn jáde ?

11 Papirusi ha dàgbà láìní ẹrẹ̀

tàbí eèsún ha dàgbà láìlómi?

12 Nígbà ó tútù, a e lulẹ̀,

ó rọ dànù, ewéko gbogbo mìíràn dípò rẹ̀.

13 Bẹ́̀ ni ipa ̀gbogbo àwọn ó gbàgbé Ọlọ́run,

bẹ́̀ ni ìrètí àwọn àgàbàgebè yóò di òfo.

14 Àbá ẹni a ó kèé kúrò,

àti ìgbẹ́kẹ̀ẹni ó dàbí ilé aláǹtakùn.

15 Yóò fi ara ti ilé rẹ̀, ṣùgbọ́n yóò dúró,

yóò fi di ara rẹ̀ ṣinṣin ṣùgbọ́n yóò dúró pẹ́.

16 Ó tutù irúgbìn a bomirin níwájú oòrùn,

̀ka rẹ̀ yọ jáde nínú ọgbà rẹ̀.

17 Gbòǹgbò rẹ̀ ta ebè ,

ó ibi òkúta wọ̀n-ọn-nì.

18 ó pa á run kúrò ipò rẹ̀,

nígbà náà ni ipò náà yóò sọ, Èmi ri !

19 Kíyèsi i, ayé rẹ̀ gbẹ dànù

àti láti inú ilẹ̀ irúgbìn òmíràn yóò jáde .

20 "Kíyèsi i, Ọlọ́run yóò ta ẹni òtítọ́ ,

bẹ́̀ ni yóò ran oníwà búburú lọ́wọ́

21 títí yóò fi fi ̀rín kún ẹnu,

àti ètè rẹ pẹ̀ìhó ayọ̀,

22 ìtìjú a o fi bo àwọn ó kórìíra rẹ̀,

àti ibùjókòó ènìyàn búburú yóò mọ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também